10 versículos bíblicos para enviar no natal
O Natal é uma época especial para refletirmos sobre o nascimento de Jesus e a alegria que Ele trouxe ao mundo. Compartilhar versículos bíblicos é uma maneira maravilhosa de lembrar do verdadeiro significado dessa data. Aqui estão 10 versículos que podem trazer luz, paz e esperança para os corações daqueles que você ama:
1. Lucas 2:10-11
O anjo traz a mensagem da grande alegria que é o nascimento de Cristo.
Angẹli náà sì wí fún wọn pé, "Má bẹ̀rù: sá wò ó, mo mú ìyìnrere ayọ̀ ńlá fún yín wá, tí yóò ṣe ti ènìyàn gbogbo. Nítorí a ti bí Olùgbàlà fún yín lónìí ní ìlú Dafidi, tí í ṣe Kristi Olúwa.
2. João 3:16
O versículo mais conhecido, que nos lembra do amor de Deus pelo mundo e do presente de Jesus para a salvação da humanidade.
"Nítorí Ọlọ́run fẹ́ aráyé tó bẹ́ẹ̀ gẹ́ẹ́, tí ó fi ọmọ rẹ̀ kan ṣoṣo fún ni, kí ẹnikẹ́ni tí ó bá gbà á gbọ́, má bà á ṣègbé, ṣùgbọ́n kí ó lè ní ìyè àìnípẹ̀kun.
3. Isaías 9:6
Uma profecia que revela o papel de Cristo como o Príncipe da Paz.
Nítorí a bí ọmọ kan fún wa,
a fi ọmọkùnrin kan fún wa,
ìjọba yóò sì wà ní èjìká rẹ̀.
A ó sì máa pè é ní
Ìyanu Olùdámọ̀ràn, Ọlọ́run Alágbára,
Baba ayérayé, Ọmọ ọba aládé Àlàáfíà.
4. Mateus 1:23
Este versículo nos lembra da presença de Deus conosco em Jesus.
"Wúńdíá kan yóò lóyún, yóò sì bí ọmọkùnrin kan, yóò sì pe orúkọ rẹ̀ ní Emmanueli," (èyí tí ó túmọ̀ sí "Ọlọ́run wà pẹ̀lú wa").
5. Lucas 1:30-31
O anúncio do nascimento de Jesus a Maria, que nos lembra da graça de Deus.
Ṣùgbọ́n angẹli náà wí fún un pé, "Má bẹ̀rù, Maria, nítorí ìwọ ti rí ojúrere lọ́dọ̀ Ọlọ́run. Ìwọ yóò lóyún nínú rẹ, ìwọ ó sì bí ọmọkùnrin kan, ìwọ ó sì pe orúkọ rẹ̀ ní Jesu.
6. 2 Coríntios 9:15
Uma expressão simples, mas profunda, de gratidão por Jesus, o maior presente de todos.
Ọpẹ́ ni fún Ọlọ́run nítorí aláìlèfẹnusọ ẹ̀bùn rẹ̀!
7. Gálatas 4:4-5
Este versículo lembra que o nascimento de Jesus teve um propósito divino: nossa adoção como filhos de Deus.
Ṣùgbọ́n nígbà tí àkókò kíkún náà dé, Ọlọ́run rán ọmọ rẹ̀ jáde wá, ẹni tí a bí nínú obìnrin tí a bí lábẹ́ òfin. Láti ra àwọn tí ń bẹ lábẹ́ òfin padà, kí àwa lè gba ìsọdọmọ.
8. João 1:14
A encarnação de Cristo, um grande mistério da nossa fé, que traz a presença de Deus à Terra.
Ọ̀rọ̀ náà sì di ara, òun sì ń bá wa gbé. Àwa sì ti rí ògo rẹ̀, àní ògo ọmọ rẹ kan ṣoṣo, tí ó ti ọ̀dọ̀ Baba wá, ó kún fún oore-ọ̀fẹ́ àti òtítọ́.
9. Colossenses 1:19
A plena presença de Deus em Jesus, que é a expressão de Deus em carne.
Nítorí ìfẹ́ Ọlọ́run ni pé kí gbogbo ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ òun tìkára rẹ̀ lè máa gbé nínú rẹ̀.
10. Lucas 2:14
A mensagem dos anjos aos pastores, proclamando a paz trazida pelo nascimento de Jesus.
"Ògo ni fún Ọlọ́run lókè ọ̀run,
àti ní ayé àlàáfíà, ìfẹ́ inú rere sí ènìyàn."
Esses versículos são perfeitos para compartilhar o amor de Deus com os outros durante o Natal, lembrando-nos da dádiva preciosa que recebemos através do nascimento de Jesus. Que a paz e a alegria que Ele trouxe ao mundo estejam com todos neste Natal.
Se este artigo te ajudou, faça sua parte e compartilhe a Palavra de Deus com aqueles que você ama.