Publicidade

1 João 2

1 ̀yin ọmọ mi ̀wọ́n, mo kọ ìwé nǹkan wọ̀nyí yín, ̀yin á dẹ́ṣẹ̀. Ṣùgbọ́n ẹnikẹ́ni dẹ́ṣẹ̀, àwa ni alágbàwí lọ́dọ̀ Baba: Jesu Kristi, olódodo nìkan. 2 Òun ètùtù fún ̀ṣẹ̀ wa, í tilẹ̀ ṣe fún tiwa nìkan ṣùgbọ́n fún ̀ṣẹ̀ gbogbo aráyé.

3 Àwa mọ̀ àwa ti mọ̀ ́n, àwa ń pa òfin rẹ̀ mọ́. 4 Ẹni ó , "Èmi mọ̀ ́n," pa òfin rẹ̀ mọ́, èké ni, òtítọ́ ṣí nínú rẹ̀. 5 Ṣùgbọ́n ẹnikẹ́ni ó ń pa òfin rẹ̀ mọ́, lára rẹ̀ ni a gbé ìfẹ́ Ọlọ́run nítòótọ́. Nípa èyí ni àwa mọ̀ àwa ń nínú rẹ̀. 6 Ẹnikẹ́ni ó òun ń gbé inú rẹ̀, òun náà pẹ̀yẹ láti máa rìn gẹ́gẹ́ Jesu ti rìn.

7 ̀yin olùfẹ́ ̀wọ́n, í ṣe òfin tuntun ni mo ń kọ̀rẹ̀ yín ṣùgbọ́n òfin àtijọ́, èyí ̀yin gbọ́ àtètèkọ́ṣe. Òfin àtijọ́ ni ̀rọ̀ náà ̀yin gbọ́. 8 Pẹ̀lúpẹ̀, òfin tuntun ni mo ń kọ̀rẹ̀ yín; èyí í ṣe òtítọ́ nínú rẹ̀ àti nínú yin, nítorí òkùnkùn ń kọjá lọ, ìmọ́lẹ̀ òtítọ́ ń tàn.

9 Ẹni ó òun ń nínú ìmọ́lẹ̀, ó kórìíra arákùnrin rẹ̀ ń bẹ nínú òkùnkùn. 10 Ẹni ó ba fẹ́ràn arákùnrin rẹ̀, ó ń gbé inú ìmọ́lẹ̀, ṣí ohun ìkọ̀sẹ̀ kan nínú rẹ̀. 11 Ṣùgbọ́n ẹni o kórìíra arákùnrin rẹ̀ ń gbé nínú òkùnkùn, ó ń rìn nínú òkùnkùn; mọ ibi òun ń lọ, nítorí òkùnkùn fọ́ lójú.

12 Èmi ń kọ̀yín, ̀yin ọmọ mi ̀wọ́n,

nítorí a darí ̀ṣẹ̀ yín yín nítorí orúkọ rẹ̀.

13 Èmi ń kọ̀yín, ̀yin baba,

nítorí ̀yin mọ ẹni ó àtètèkọ́ṣe,

Èmi ń kọ̀yín, ̀yin ̀dọ́mọkùnrin,

nítorí ̀yin ti ṣẹ́gun ẹni ibi náà.

14 Èmi ń kọ̀yín, ̀yin ọmọdé mi ̀wọ́n,

nítorí ̀yin ti mọ Baba.

Èmi ń kọ̀yín, ̀yin baba,

nítorí ti ̀yin mọ ẹni o ni àtètèkọ́ṣe.

Èmi ń kọ̀yín, ̀yin ̀dọ́mọkùnrin,

nítorí ̀yin ni agbára,

̀rọ̀ Ọlọ́run ń gbé nínú yín,

ṣẹ́gun ẹni ibi náà.

ṣe fẹ́ràn ayé

15 ṣe fẹ́ràn ayé tàbí ohunkóhun ń bẹ nínú ayé. ẹnikẹ́ni fẹ́ràn ayé, ìfẹ́ Baba nínú rẹ̀. 16 Nítorí ohun gbogbo ń bẹ nínú ayé: ìfẹ́kúfẹ̀́ ti ara, ìfẹ́kúfẹ̀́ ti ojú, àti ìgbéraga ti ohun ti ó àti ohun ó ṣe láti ̀dọ̀ Baba ṣe láti ọwọ́ ayé. 17 Ayé ń kọjá lọ àti ìfẹ́kúfẹ̀́ rẹ̀, ṣùgbọ́n ẹni ó ba ń ṣe ìfẹ́ Ọlọ́run ni yóò títí láéláé.

Ìkìlọ̀ nípa àwọn aṣòdì Kristi

18 ̀yin ọmọ mi ̀wọ́n, ìgbà ìkẹyìn ni èyí; ̀yin gbọ́ aṣòdì Kristi ń bọ̀ , àní nísinsin yìí, púpọ̀ aṣòdì Kristi ń bẹ. Nípa èyí ni àwa fi mọ́ ìgbà ìkẹyìn ni èyí. 19 Wọ́n ti ̀dọ̀ jáde, ṣùgbọ́n wọn í ṣe ara wa. Nítorí wọ́n jẹ́ ara wa, wọn ìbá wa dúró, ṣùgbọ́n jíjáde lọ wọn fihàn gbogbo wọn í ṣe ara wa.

20 Ṣùgbọ́n ̀yin ìfòróróyàn láti ̀dọ̀ ̀Mímọ́ , gbogbo yín mọ òtítọ́. 21 Èmi kọ̀yín nítorí ̀yin mọ òtítọ́, ṣùgbọ́n nítorí ̀yin mọ̀ ́n, àti èké nínú òtítọ́. 22 Ta ni èké? Ẹni ó sẹ́ Jesu í ṣe Kristi. Eléyìí ni Aṣòdì Kristi, ẹni ó sẹ́ Baba àti Ọmọ. 23 Ẹnikẹ́ni o ba sẹ́ Ọmọ, gba Baba; ṣùgbọ́n ẹni ó ba jẹ́wọ́ Ọmọ, ó gba Baba pẹ̀.

24 jẹ́ èyí gbọ́ ni àtètèkọ́ṣe máa gbé inú yín. èyí ̀yin gbọ́ àtètèkọ́ṣe ń gbé inú yín, ̀yin ó dúró nínú Ọmọ àti nínú Baba. 25 Èyí ni ìlérí náà ó ṣe fún wa, àní ìyè àìnípẹ̀kun.

26 Nǹkan wọ̀nyí ni mo kọ̀yín ti àwọn wọ́n fẹ́ yín ṣìnà. 27 Ṣùgbọ́n ti ìfòróróyàn ̀yín gba lọ́wọ́ rẹ̀ ṣì ń gbé inú yín, ̀yin tún nílò ẹnìkan kọ yín. Ṣùgbọ́n ìfòróróyàn náà ti ń kọ́ yín ohun gbogbo ó jẹ́ òtítọ́, í í ṣe èké, àní gẹ́gẹ́ ó ti kọ́ yín, máa gbé inú rẹ̀.

Àwọn ọmọ Ọlọ́run

28 Àti nísinsin yìí, ̀yin ọmọ mi ̀wọ́n, máa gbé inú rẹ̀, nígbà òun ó farahàn, a ni ìgboyà níwájú rẹ̀, ojú níwájú rẹ̀ ni ìgbà wíwá rẹ̀.

29 ̀yin ba mọ̀ olódodo ni òun, mọ̀ a olúkúlùkù ẹni ń ṣe òdodo nípa rẹ̀.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-