Publicidade

1 Pedro 5

àwọn alàgbà àti àwọn ̀dọ́kùnrin

1 Àwọn alàgbà ń bẹ láàrín yín ni mo gbànímọ̀ràn, èmi ẹni ń ṣe alàgbà ̀yin, àti ẹlẹ́rìí ìyà Kristi, àti alábápín nínú ògo a ó fihàn. 2 máa tọ́agbo Ọlọ́run ń bẹ láàrín yín, máa bojútó o, í ṣe àfipáṣe, ṣe tìfẹ́tìfẹ́; jẹ́ fún èrè ìjẹkújẹ, ṣe pẹ̀ìpinnu ó múra tan. 3 Bẹ́̀ ni í ṣe ẹni ń lo agbára lórí ìjọ, ṣùgbọ́n ṣe ara yín àpẹẹrẹ fún agbo. 4 Nígbà Olórí Olùṣọ́-àgùntàn fi ara hàn, ̀yin ó gba adé ògo ti í .

5 Bẹ́̀ pẹ̀, ̀yin ̀dọ́, tẹríba fún àwọn alàgbà. Àní, gbogbo yín máa tẹríba fún ara yín fi ìrẹ̀lẹ̀ wọ ara yín aṣọ: nítorí,

"Ọlọ́run kọ ojú ìjà àwọn agbéraga,

ṣùgbọ́n ó ń fi oore-ọ̀fẹ́ fún àwọn onírẹ̀lẹ̀."

6 Nítorí náà, rẹ ara yin sílẹ̀ lábẹ́ ọwọ́ agbára Ọlọ́run, òun gbe yín ga lákokò. 7 máa gbogbo àníyàn yín e; nítorí òun ń ṣe ìtọ́yín.

8 máa ni àìrékọjá, máa ṣọ́ra; nítorí èṣù ̀yín, i kìnnìún ń ramúramù, ó ń rìn káàkiri, ó ń wa ẹni yóò pajẹ. 9 kọ ojú ìjà i pẹ̀ìdúró ṣinṣin nínú ìgbàgbọ́, ̀yin ti mọ̀ ìyà kan náà ni àwọn ará yín ń bẹ nínú ayé ń jẹ.

10 Ọlọ́run oore-ọ̀fẹ́ gbogbo, ó ti yín sínú ògo rẹ̀ nípẹ̀kun nínú Kristi Jesu, nígbà ̀yin ti jìyà díẹ̀, òun tìkára rẹ̀, yóò ṣe yín àṣepé, yóò fi ẹsẹ̀ yín múlẹ̀, yóò fún yín lágbára, yóò fi ìdí yín kalẹ̀. 11 Tìrẹ ni ògo àti agbára títí láé. Àmín.

Àwọn ìkíni ìkẹyìn

12 Nítorí Sila, arákùnrin wa olóòtítọ́ gẹ́gẹ́ mo ti á , ni mo kọ̀kúkúrú i yín, mo ń gbà yín níyànjú, mo ń jẹ́rìí , èyí ni òtítọ́ oore-ọ̀fẹ́ Ọlọ́run: dúró ṣinṣin nínú rẹ̀.

13 Ìjọ ń bẹ Babeli, a yàn, pẹ̀yín, bẹ́̀ ni Marku ọmọ mi pẹ̀.

14 fi ìfẹ́nukonu ìfẹ́ ara, yín.

Àlàáfíà fún gbogbo yín nínú Kristi.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-