Pular para o conteúdo
Publicidade

2 Kọrinti 5

Iṣẹ́ ìránṣẹ́ ìlàjà a sọ́tọ̀

11 Nítorí náà àwa ti mọ ̀Olúwa, àwa ń ènìyàn lọ́kàn padà; ṣùgbọ́n a ń fi hàn fún Ọlọ́run; mo gbàgbọ́ , a ti hàn ọkàn yín pẹ̀. 12 5.12: 2Kọ 3.1.Nítorí àwa máa tún yin ara i yín mọ́, ṣùgbọ́n àwa fi ààyè fún yín láti máa ṣògo nítorí wa, ohun ̀yin yóò fi wọn lóhùn, àwọn ti ń ṣògo lóde ara í ṣe ọkàn. 13 Nítorí náà àwa ń sínwín, fún Ọlọ́run ni tàbí iyè ṣí pépé, fún yín ni. 14 5.14: Ro 5.15; 6.6-7.Nítorí ìfẹ́ Kristi ń rọ̀ , nítorí àwa mọ̀ báyìí , ẹnìkan fún gbogbo ènìyàn, ǹjẹ́ nígbà náà, gbogbo wọ́n ni ó ti . 15 Ó ti fún gbogbo wọn, àwọn ó láààyè ṣe láààyè fún ara wọn mọ́, ṣe fún ẹni ó nítorí wọn, ó ti jíǹde.

16 Nítorí náà láti ìsinsin yìí lọ, àwa mọ ẹnìkan nípa ti ara mọ́; àwa tilẹ̀ ti mọ Kristi nípa ti ara, ṣùgbọ́n nísinsin yìí àwa mọ̀ ́n bẹ́̀ mọ́. 17 5.17: Ro 16.7; Ga 6.15.Nítorí náà ẹnìkan nínú Kristi, ó di ̀tuntun: ohun àtijọ́ ti kọjá lọ; kíyèsi i, ohun tuntun ti . 18 5.18: 1Kọ 11.12; Kl 1.20; Ro 5.10.Ohun gbogbo ti ̀dọ̀ Ọlọ́run , ẹni ó tipasẹ̀ Jesu Kristi wa làjà sọ́dọ̀ ara rẹ̀, ó ti fi iṣẹ́ ìránṣẹ́ ìlàjà fún wa. 19 Èyí ni , Ọlọ́run nínú Kristi, ó ń aráyé làjà sọ́dọ̀ ara rẹ̀, ka ìrékọjá wọn wọn lọ́rùn; ó ti fi ̀rọ̀ ìlàjà wa lọ́wọ́. 20 5.20: Ef 6.20.Nítorí náà àwa ni ikọ̀ fún Kristi, ẹni Ọlọ́run ń ti ̀dọ̀ wa ṣìpẹ̀ fún yín: àwa ń bẹ̀ yín ipò Kristi, "Ọlọ́run làjà." 21 5.21: Hb 4.15; 7.25; 1Pt 2.22; 1Jh 3.5; Ap 3.14.Nítorí ó fi í ṣe ̀ṣẹ̀ nítorí wa, ẹni mọ ̀ṣẹ̀kẹ́ṣẹ̀ , àwa di òdodo Ọlọ́run nínú rẹ̀.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também