Publicidade

2 Tessalonicenses 1

1 Paulu, Sila àti Timotiu,

ìjọ Tẹsalonika, nínú Ọlọ́run Baba wa àti Jesu Kristi Olúwa:

2 Oore-ọ̀fẹ́ àti àlàáfíà fún yín láti ̀dọ̀ Ọlọ́run Baba àti Jesu Kristi Olúwa.

Ìdúpẹ́ àti àdúrà

3 Ó yẹ a máa dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọ́run nígbà gbogbo nítorí yín, ará, àní gẹ́gẹ́ ó ti yẹ, nítorí ìgbàgbọ́ yín ń dàgbà gidigidi, àti ìfẹ́ olúkúlùkù yín ara yín ń di púpọ̀. 4 Nítorí náà, àwa tìkára wa ń fi yín ṣògo nínú ìjọ Ọlọ́run, nítorí sùúrù àti ìgbàgbọ́ yín nínú gbogbo inúnibíni àti wàhálà yín ̀yin náà ń fi ara .

5 Àwọn nǹkan wọ̀nyí jẹ́ ̀òdodo ni ìdájọ́ Ọlọ́run àti nítorí èyí ni a ó yín yẹ fún ìjọba Ọlọ́run, nítorí èyí ̀yin pẹ̀ṣe ń jìyà. 6 Olódodo ni Ọlọ́run: Òun yóò pọ́n àwọn ń pọ́n yín lójú, lójú, 7 Òun yóò fi ìtura fún ̀yin a ti pọ́n lójú àti fún àwa náà pẹ̀. Èyí yóò ṣe nígbà ìfarahàn Jesu Olúwa láti ̀run fún nínú ọwọ́ iná pẹ̀àwọn angẹli alágbára. 8 Òun yóò fi ìyà jẹ àwọn mọ Ọlọ́run àti àwọn ń ṣe àìgbọ́ràn ìyìnrere Jesu Olúwa wa. 9 A ó fi ìparun àìnípẹ̀kun jẹ wọ́n , a ó ṣe wọn mọ̀ kúrò níwájú Olúwa àti inú ògo agbára rẹ̀, 10 ọjọ́ yóò jẹ́ ẹni a ó yìn lógo nínú àwọn ènìyàn mímọ́ rẹ̀ àti ẹni àwòyanu àárín gbogbo àwọn ó ti gbàgbọ́. Èyí yọ yín sílẹ̀, nítorí ti gba ̀a jẹ́ yín gbọ́.

11 Nítorí èyí, àwa pẹ̀ń gbàdúrà fún un yín nígbà gbogbo, Ọlọ́run wa ó yín yẹ fún ìpè rẹ̀, àti nípa agbára rẹ̀, òun yóò gbogbo èrò rere yín ṣẹ àti gbogbo ohun ìgbàgbọ́ jáde. 12 Wọ̀nyí ni àdúrà wa, orúkọ Jesu Olúwa wa di yíyìn lógo nínú yín àti ̀yin nínú rẹ̀, gẹ́gẹ́ oore-ọ̀fẹ́ Ọlọ́run àti ti Jesu Kristi Olúwa.

Veja também

Publicidade
2 Tessalonicenses
Ver todos os capítulos de 2 Tessalonicenses
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-