Publicidade

3 João 1

1 Alàgbà,

Gaiusi, olùfẹ́, ẹni mo fẹ́ nínú òtítọ́.

2 Olùfẹ́, èmi ń gbàdúrà nínú ohun gbogbo o máa dára fún , o máa ni ìlera, àní o dára fún ọkàn rẹ. 3 Nítorí mo yọ̀ gidigidi, nígbà àwọn arákùnrin wọn jẹ́rìí ìwà òtítọ́ inú rẹ̀, àní ìwọ ń rìn nínú òtítọ́. 4 Èmi ni ayọ̀ ó tayọ, láti máa gbọ́ , àwọn ọmọ mi ń rìn nínú òtítọ́.

5 Olùfẹ́, ìwọ ń ṣe olóòtítọ́ nínú iṣẹ́ ìwọ ń ṣe fún àwọn ń ṣe ará, àti pàápàá fún àwọn ń ṣe àlejò. 6 wọn ń jẹ́rìí ìfẹ́ rẹ̀ níwájú ìjọ, ìwọ ń pèsè fún wọn ̀àjò wọn gẹ́gẹ́ ó yẹ nínú Ọlọ́run. 7 Nítorí , nítorí iṣẹ́ Kristi ni wọ́n ṣe jáde lọ, láìgba ohunkóhun lọ́wọ́ àwọn aláìkọlà. 8 Nítorí náà, ó yẹ àwa fi inú rere gba irú àwọn wọ̀nyí, àwa jẹ́ alábáṣiṣẹ́pọ̀ pẹ̀òtítọ́.

9 Èmi kọ̀ìjọ ṣùgbọ́n Diotirefe, ẹni ó fẹ́ láti jẹ́ ẹni pàtàkì jùlọ, gbà . 10 Nítorí náà mo , èmi yóò iṣẹ́ rẹ̀ ó ṣe ìrántí rẹ, ó ń sọ ̀rọ̀ búburú àti ìsọkúsọ wa, èyí tún tẹ́ lọ́rùn, síbẹ̀ òun fúnra rẹ̀ kọ̀ láti gba àwọn ará, àwọn ó ń fẹ́ gbà wọ́n, ó ń wọn lẹ́kun, ó ń wọn kúrò nínú ìjọ.

11 Olùfẹ́, ṣe ṣe àfarawé ohun í ṣe ibi ṣe ohun ṣe rere. Ẹni ó ń ṣe rere ti Ọlọ́run ni; ẹni ó ba ń ṣe búburú Ọlọ́run. 12 Demetriusi ̀rere lọ́dọ̀ gbogbo ènìyàn àti ti òtítọ́ fúnra rẹ̀ pẹ̀; nítòótọ́, àwa pẹ̀gba ̀rẹ̀ jẹ́; ̀yin mọ̀ , òtítọ́ ni ̀wa.

13 Èmí ohun púpọ̀ láti kọ sínú ìwé , ṣùgbọ́n èmi fẹ́ fi kálàmù àti tawada kọ wọ́n sínú ìwé. 14 Mo ni ìrètí láti láìpẹ́, àwa yóò sọ̀rọ̀ lójúkojú.

15 Àlàáfíà fún .

Àwọn ̀rẹ́ wa níbí . àwọn ̀rẹ́ wa lọ́dọ̀ rẹ ̀kọ̀̀kan.

Veja também

Publicidade
3 João
Ver todos os capítulos de 3 João
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-