Publicidade

Efésios 1

1 Paulu, aposteli Jesu Kristi nípa ìfẹ́ Ọlọ́run,

àwọn ènìyàn mímọ́ ó Efesu, àti àwọn olóòtítọ́ nínú Kristi Jesu:

2 Oore-ọ̀fẹ́ yín àti àlàáfíà láti ̀dọ̀ Ọlọ́run Baba àti Jesu Kristi Olúwa.

Ìbùkún ti ̀Mímọ́ nínú Kristi

3 Ògo ni fún Ọlọ́run àti Baba Jesu Kristi Olúwa wa, ẹni ó ti bùkún wa láti inú ̀run pẹ̀àwọn ìbùkún ̀gbogbo nínú Kristi. 4 Àní, gẹ́gẹ́ o ti yàn nínú rẹ̀ ṣáájú ìpilẹ̀ṣẹ̀ ayé, láti jẹ́ mímọ́ àti aláìlábùkù níwájú rẹ̀ nínú ìfẹ́ 5 ẹni ò ti yàn tẹ́lẹ̀ ìsọdọmọ nípa Jesu Kristi fún ara rẹ̀, ìbámu ìdùnnú ìfẹ́ rẹ̀, 6 fún ìyìn ògo oore-ọ̀fẹ́ rẹ̀, èyí ò ti fi fún wa nínú Àyànfẹ́ rẹ̀. 7 Nínú rẹ̀ ni àwa ìràpadà gba nípa ̀jẹ̀ rẹ̀ àti ìdáríjì àwọn ̀ṣẹ̀ wa, ìbámu pẹ̀ọrọ̀ oore-ọ̀fẹ́ Ọlọ́run 8 èyí ó fún wa lọ́pọ̀lọ́pọ̀ pẹ̀gbogbo ọgbọ́n àti ìmòye, 9 Ó ti sọ ohun ìjìnlẹ̀ ìfẹ́ rẹ̀ di mọ̀ fún wa gẹ́gẹ́ ìdùnnú rere rẹ̀, èyí ti o pinnu nínú Kristi, 10 èyí yóò jẹ jáde kíkún àkókò, láti ṣe àkójọpọ̀ àwọn ohun ̀run àti ti ayé lábẹ́ Kristi.

11 Nínú rẹ̀ ni a yàn fẹ́ lẹ́yìn ó ti yàn tẹ́lẹ̀ gẹ́gẹ́ ìpinnu ẹni ń ṣiṣẹ́ ohun gbogbo ìbámu ìfẹ́ rẹ̀, 12 àwa ó le fún ìyìn ògo rẹ̀, àwa a ti ni ìrètí ṣáájú nínú Kristi. 13 Àti ̀yin pẹ̀darapọ̀ nínú Kristi nígbà ̀yin gbọ́ ̀rọ̀ òtítọ́ náà àní ìyìnrere ìgbàlà yin. Nígbà ̀yin gbàgbọ́, a fi ̀Mímọ́ ṣe èdìdì ayé yin nínú rẹ, èyí a ti ṣe ìlérí rẹ̀ tẹ́lẹ̀, 14 èyí ó jẹ́ ìdánilójú àṣansílẹ̀ ogún wa títí yóò fi di àkókò ìràpadà àwọn í ṣe ti Ọlọ́run ìyìn ògo rẹ̀.

Ìdúpẹ́ àti àdúrà

15 Nítorí ìdí èyí, nígbà mo ti gbúròó ìgbàgbọ́ ti ń bẹ láàrín yín nínú Jesu Olúwa, àti ìfẹ́ yín gbogbo àwọn ènìyàn mímọ́. 16 Èmi sinmi láti máa dúpẹ́ nítorí yín, àti láti máa rántí yín nínú àdúrà mi. 17 Mo ń béèrè nígbà gbogbo Ọlọ́run Jesu Kristi Olúwa wa, Baba ògo, fún yín ni ̀nípa ti ọgbọ́n àti ti ìfihàn ̀yin ó tún mọ̀ ́n i. 18 Mo tún ń gbàdúrà bákan náà ojú ọkàn yín mọ́lẹ̀; ̀yin mọ ohun ìrètí ìpè rẹ̀ jẹ́, àti ọrọ̀ ògo rẹ̀ èyí í ṣe ogún àwọn ènìyàn mímọ́, 19 àti aláìlẹ́gbẹ́ títóbi agbára rẹ̀ fún àwa a gbàgbọ́. Gẹ́gẹ́ iṣẹ́ agbára rẹ̀, 20 èyí ó fi sínú Kristi, nígbà o ti dìde kúrò nínú òkú, ó un jókòó lọ́wọ́ ̀tún nínú àwọn ̀run. 21 Ó gbéga ju gbogbo ìjọba, àti àṣẹ, àti agbára, àti òye àti gbogbo orúkọ a ń , í ṣe ni ayé yìí nìkan, ṣùgbọ́n ni èyí ń bọ̀ pẹ̀. 22 Ọlọ́run ti fi ohun gbogbo sábẹ́ ẹsẹ̀ rẹ̀, ó fi í ṣe orí lórí ohun gbogbo fún ìjọ, 23 èyí i ṣe ara rẹ̀, ̀kúnrẹ́rẹ́ ẹni ó kún ohun gbogbo gbogbo ̀.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-