Publicidade

Gálatas 5

Òmìnira nínú Jesu

1 Nítorí náà, dúró ṣinṣin nínú òmìnira náà èyí Kristi fi sọ di òmìnira, ṣe tún fi ọrùn bọ̀ àjàgà ẹrú mọ́.

2 Kíyèsi i, èmi Paulu ni ó fún yín , a kọ yín nílà abẹ́, Kristi yóò lérè fún yín ohunkóhun. 3 Mo tún sọ fún olúkúlùkù ènìyàn a kọ ilà , ó di ajigbèsè láti pa gbogbo òfin mọ́. 4 A ti yín kúrò lọ́dọ̀ Kristi, ̀yin ń fẹ́ a yín láre nípa òfin; ti ṣubú kúrò nínú oore-ọ̀fẹ́. 5 Nítorí nípa ̀àwa ń fi ìgbàgbọ́ dúró de ìrètí òdodo. 6 Nítorí nínú Kristi Jesu, ìkọlà jẹ́ ohun kan, tàbí àìkọlà; ṣùgbọ́n ìgbàgbọ́ ti ń ṣiṣẹ́ nípa ìfẹ́.

7 ̀yin ti ń sáré dáradára. Ta ni yin lọ́wọ́ láti ṣe ìgbọ́ràn òtítọ́? 8 Ìyípadà yìí ti ̀dọ̀ ẹni ó yín . 9 Ìwúkàrà díẹ̀ í gbogbo ìyẹ̀fun . 10 Mo ìgbẹ́kẹ̀yín nínú Olúwa , ̀yin yóò èrò ohun mìíràn; ṣùgbọ́n ẹni ń yọ yín lẹ́nu yóò ru ìdájọ́ tirẹ̀, ẹnikẹ́ni ó ó jẹ́. 11 Ṣùgbọ́n, ará, èmi ń wàásù ìkọlà síbẹ̀, kín ni ìdí a fi ń ṣe inúnibíni mi síbẹ̀? Ǹjẹ́ ìkọ̀sẹ̀ àgbélébùú ti kúrò. 12 Èmi ìbá fẹ́ àwọn ń yọ yín lẹ́nu tilẹ̀ ̀ara wọn kan kúrò.

13 Nítorí a ti yín òmìnira, ará kìkì ṣe lo òmìnira yín àǹfààní sípa ti ara, ṣùgbọ́n máa fi ìfẹ́ sin ọmọnìkejì yín. 14 Nítorí a gbogbo òfin nínú èyí , "Ìwọ fẹ́ ọmọnìkejì rẹ gẹ́gẹ́ ara rẹ." 15 Ṣùgbọ́n ̀yin ń bu ara yín ṣán, ń jẹ ara yín run, kíyèsára ṣe pa ara yín run.

Ìyè nípa ti ̀

16 Ǹjẹ́ mo , máa rìn nípa ti ̀, ̀yin yóò ìfẹ́kúfẹ̀́ ti ara ṣẹ. 17 Nítorí ti ara ń ṣe ìfẹ́kúfẹ̀́ lòdì ̀, àti ̀lòdì ara, àwọn wọ̀nyí lòdì ara wọn; ba à ṣe ohun ̀yin ń fẹ́. 18 Ṣùgbọ́n a ń ti ọwọ́ ̀ṣamọ̀yín, ̀yin lábẹ́ òfin.

19 Ǹjẹ́ àwọn iṣẹ́ ara farahàn, í ṣe wọ̀nyí; panṣágà, àgbèrè, ìwà èérí, wọ̀bìà, 20 Ìbọ̀rìṣà, oṣó, ìkórìíra, ìjà, ìlara, ìbínú, ìmọ-tara-ẹni nìkan, ìyapa, ̀kọ́ òdì. 21 Àrankàn, ìpànìyàn, ìmutípara, ìréde òru, àti irú ìwọ̀nyí; àwọn ohun mo ń fún yín tẹ́lẹ̀, gẹ́gẹ́ mo ti fún yín tẹ́lẹ̀ , àwọn ń ṣe nǹkan báwọ̀nyí yóò jogún ìjọba Ọlọ́run.

22 Ṣùgbọ́n èso ti ̀ni ìfẹ́, ayọ̀, àlàáfíà, ìpamọ́ra, ìwà pẹ̀lẹ́, ìṣoore, ìgbàgbọ́, 23 ìwà tútù, àti ìkóra-ẹni níjanu, òfin kan lòdì irú wọ̀nyí, 24 Àwọn í ṣe ti Kristi Jesu ti kan ara wọn mọ́ àgbélébùú pẹ̀ìfẹ́ àti ìfẹ́kúfẹ̀́ rẹ̀. 25 àwa láààyè sípa ti ̀, jẹ́ a máa rìn nípa ti ̀. 26 ṣe jẹ́ a máa ṣe ògo asán, a ọmọnìkejì wa bínú, a ṣe ìlara ọmọnìkejì wa.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-