Publicidade

João 2

Jesu sọ omi di ọtí wáìnì

1 ọjọ́ kẹta, wọn ń ṣe ìgbéyàwó kan Kana ti Galili. Ìyá Jesu níbẹ̀. 2 A pe Jesu àti àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ ibi ìgbéyàwó náà. 3 Nígbà wáìnì tán, ìyá Jesu fún un , "Wọn wáìnì mọ́."

4 Jesu fèsì , "Arábìnrin ̀wọ́n, èéṣe ̀rọ̀ yìí fi kàn ? Àkókò mi ì ."

5 Ìyá rẹ̀ fún àwọn ìránṣẹ́ náà , "ṣe ohunkóhun ó fún yín."

6 Ìkòkò òkúta omi mẹ́ni a gbé kalẹ̀ níbẹ̀, irú èyí àwọn Júù máa ń fi ṣe ìwẹ̀, èyí ̀kọ̀̀kan wọn gbà ìwọ̀n ogún ọgbọ̀n jálá.

7 Jesu fún àwọn ìránṣẹ́ náà , "pọn omi kún ìkòkò wọ̀nyí." Wọ́n pọn omi kún wọn títí etí.

8 Lẹ́yìn náà ni ó fún wọn , "jáde lára rẹ̀ gbé e tọ alábojútó àsè lọ."

Wọ́n gbé e lọ; 9 alábojútó àsè náà tọ́ omi a sọ di wáìnì . Òun mọ ibi ó ti , ṣùgbọ́n àwọn ìránṣẹ́ ó bu omi náà mọ̀. Alábojútó àsè pe ọkọ ìyàwó apá kan, 10 Ó fún un , "Olúkúlùkù a máa kọ́kọ́ gbé wáìnì ó dára jùlọ kalẹ̀; nígbà àwọn ènìyàn mu ún tan, nígbà náà wọn a èyí dára bẹ́̀ ; ṣùgbọ́n ìwọ ti pa wáìnì dáradára yìí mọ́ títí ó fi di ìsinsin yìí."

11 Èyí jẹ́ àkọ́ṣe iṣẹ́ àmì, Jesu ṣe Kana ti Galili. Ó fi ògo rẹ̀ hàn; àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ gbà á gbọ́.

Jesu ṣe àfọ̀mọ́ tẹmpili

12 Lẹ́yìn èyí, ó sọ̀kalẹ̀ lọ Kapernaumu, Òun àti ìyá rẹ̀ àti àwọn arákùnrin rẹ̀, àti àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, wọ́n gbé ibẹ̀ ọjọ́ pípẹ́.

13 Àjọ ìrékọjá àwọn Júù súnmọ́ etílé, Jesu gòkè lọ Jerusalẹmu, 14 Ó àwọn n ta màlúù, àti àgùntàn, àti àdàbà, àti àwọn onípàṣípàrọ̀ owó nínú tẹmpili wọ́n jókòó: 15 Ó fi okùn tẹ́́rẹ́ ṣe pàṣán, ó gbogbo wọn jáde kúrò nínú tẹmpili, àti àgùntàn àti màlúù; ó da owó àwọn onípàṣípàrọ̀ owó , ó si ti tábìlì wọn ṣubú. 16 Ó fún àwọn ń ta àdàbà , "gbé nǹkan wọ̀nyí kúrò níhìn-ín; ṣe sọ ilé Baba mi di ilé ọjà títà." 17 Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ rántí , a ti kọ ́ , "Ìtara ilé rẹ jẹ run."

18 Nígbà náà àwọn Júù dáhùn, wọ́n bi í , "Àmì wo ni ìwọ fihàn , ìwọ fi ń ṣe nǹkan wọ̀nyí?"

19 Jesu dáhùn ó fún wọn , "tẹmpili yìí palẹ̀, Èmi ó tún un kọ ọjọ́ mẹ́ta."

20 Nígbà náà àwọn Júù , "Ọdún mẹ́rìndínláàádọ́ta ni a fi kọ́ tẹmpili yìí, ìwọ ó ha tún un kọ ọjọ́ mẹ́ta?" 21 Ṣùgbọ́n òun ń sọ ti tẹmpili ara rẹ̀. 22 Nítorí náà nígbà ó jíǹde kúrò nínú òkú, àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ rántí , ó ti sọ èyí fún wọn, wọ́n gba Ìwé Mímọ́, àti ̀rọ̀ Jesu ti sọ gbọ́.

23 Nígbà ó Jerusalẹmu, àjọ ìrékọjá, lákokò àjọ náà, ̀pọ̀ ènìyàn gba orúkọ rẹ̀ gbọ́ nígbà wọ́n iṣẹ́ àmì ó ṣe. 24 Ṣùgbọ́n Jesu gbé ara wọn, nítorí ó mọ gbogbo ènìyàn. 25 Òun nílò ̀nípa ènìyàn, nítorí o mọ̀ ohun ń bẹ nínú ènìyàn.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-