Publicidade

João 20

Òfo ibojì

1 kùtùkùtù ọjọ́ kìn-ín-ní ̀sẹ̀, nígbà ilẹ̀ ì mọ́, ni Maria Magdalene ibojì, ó i , a ti gbé òkúta kúrò lẹ́nu ibojì. 2 Nítorí náà, ó sáré, ó tọ Simoni Peteru àti ọmọ-ẹ̀yìn mìíràn , ẹni Jesu fẹ́ràn, ó fún wọn , "Wọ́n ti gbé Olúwa kúrò nínú ibojì, àwa mọ ibi wọ́n gbé tẹ́ ."

3 Nígbà náà ni Peteru àti ọmọ-ẹ̀yìn mìíràn náà jáde, wọ́n ibojì. 4 Àwọn méjèèjì jùmọ̀ sáré: èyí ọmọ-ẹ̀yìn náà sáré ya Peteru, ó kọ́kọ́ ibojì. 5 Ó bẹ̀rẹ̀ láti wo inú rẹ̀, ó aṣọ ̀gbọ̀ náà ilẹ̀; ṣùgbọ́n òun wọ inú rẹ̀. 6 Nígbà náà ni Simoni Peteru ń bọ̀ lẹ́yìn rẹ̀ , ó wọ inú ibojì, ó aṣọ ̀gbọ̀ náà ilẹ̀. 7 Àti , gèlè ó níbi orí rẹ̀ pẹ̀aṣọ ̀gbọ̀ náà, ṣùgbọ́n ó jọ ibìkan fúnra rẹ̀. 8 Nígbà náà ni ọmọ-ẹ̀yìn mìíràn náà, ẹni ó kọ́ ibojì wọ inú rẹ̀ pẹ̀, ó i, ó gbàgbọ́. 9 (Nítorí wọn à mọ ìwé mímọ́ , Jesu láti jíǹde kúrò nínú òkú). 10 Bẹ́̀ ni àwọn ọmọ-ẹ̀yìn náà tún padà lọ ilé wọn.

Jesu fi ara han Maria Magdalene

11 Ṣùgbọ́n Maria dúró létí ibojì lóde, ó ń sọkún: ó ti ń sọkún, bẹ́̀ ni ó bẹ̀rẹ̀, ó wo inú ibojì. 12 Ó kíyèsi àwọn angẹli méjì aláṣọ funfun, wọ́n jókòó, ̀kan níhà orí àti ̀kan níhà ẹsẹ̀, níbi òkú Jesu gbé ti sùn .

13 Wọ́n fún un , "Obìnrin yìí, èéṣe ìwọ fi ń sọkún?"

Ó fún wọn , "Nítorí wọ́n ti gbé Olúwa mi, èmi mọ ibi wọ́n gbé tẹ́ ." 14 Nígbà ó ti èyí tan, ó yípadà, ó Jesu dúró, mọ̀ Jesu ni.

15 Jesu fún un , "Obìnrin yìí, èéṣe ìwọ fi ń sọkún? Ta ni ìwọ ń ?"

Òun ṣe olùṣọ́gbà í ṣe, ó fún un , "Alàgbà, ìwọ ti gbé e kúrò níhìn-ín yìí, sọ ibi ìwọ tẹ́ fún mi, èmi yóò gbé e kúrò."

16 Jesu fún un , "Maria!"

Ó yípadà, ó fún un èdè Heberu , "Rabboni!" (èyí ó túmọ̀ "Olùkọ́").

17 Jesu fún un , "ṣe fi ọwọ́ kàn ; nítorí èmi ì gòkè lọ ̀dọ̀ Baba mi. Ṣùgbọ́n lọ ̀dọ̀ àwọn arákùnrin mi, fún wọn , Èmi ń gòkè lọ ̀dọ̀ Baba mi, àti Baba yín, àti ̀dọ̀ Ọlọ́run mi, àti Ọlọ́run yín.’ "

18 Maria Magdalene , ó sọ fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, "Òun ti Olúwa!" Àti , ó ti fi nǹkan wọ̀nyí fún òun.

Jesu fi ara han àwọn Aposteli

19 ọjọ́ kan náà, lọ́jọ́ kìn-ín-ní ̀sẹ̀ nígbà alẹ́ lẹ́, a ti ìlẹ̀kùn ibi àwọn ọmọ-ẹ̀yìn gbé péjọ, nítorí ìbẹ̀àwọn Júù, bẹ́̀ ni Jesu , ó dúró láàrín, ó fún wọn , "Àlàáfíà fún yín." 20 Nígbà ó ti bẹ́̀ tán, ó fi ọwọ́ àti ìhà rẹ̀ hàn wọ́n. Nígbà náà ni àwọn ọmọ-ẹ̀yìn yọ̀, nígbà wọ́n Olúwa.

21 Nítorí náà, Jesu tún fún wọn , "Àlàáfíà fún yín: gẹ́gẹ́ Baba ti rán mi, bẹ́̀ ni èmi rán yín." 22 Nígbà ó ti èyí tan, ó wọn, ó fún wọn , "gba ̀Mímọ́! 23 ̀ṣẹ̀ ẹnikẹ́ni ̀yin fi , a fi wọ́n; ̀ṣẹ̀ ẹnikẹ́ni ̀yin dádúró, a wọn dúró."

Jesu fi ara han Tomasi

24 Ṣùgbọ́n Tomasi, ̀kan nínú àwọn méjìlá, a ń Didimu, pẹ̀wọn nígbà Jesu . 25 Nítorí náà àwọn ọmọ-ẹ̀yìn ìyókù fún un , "Àwa ti Olúwa!"

Ṣùgbọ́n ó fún un , "ṣe mo àpá ìṣó ni ọwọ́ rẹ̀ èmi fi ìka mi àpá ìṣó náà, èmi fi ọwọ́ mi ìhà rẹ̀, èmi yóò gbàgbọ́!"

26 Lẹ́yìn ọjọ́ mẹ́jọ àwọn ọmọ-ẹ̀yìn tún nínú ilé, àti Tomasi pẹ̀wọn: nígbà a ti ti ìlẹ̀kùn, Jesu , ó dúró láàrín, ó , "Àlàáfíà fún yín." 27 Nígbà náà ni ó fún Tomasi , "ìka rẹ níhìn-ín yìí, o wo ọwọ́ mi; ọwọ́ rẹ níhìn-ín, o fi ìhà mi: ìwọ ṣe jẹ́ aláìgbàgbọ́ mọ́, ṣùgbọ́n jẹ́ onígbàgbọ́."

28 Tomasi dáhùn, ó fún un , "Olúwa mi àti Ọlọ́run mi!"

29 Jesu fún un , "Nítorí ìwọ mi ni ìwọ ṣe gbàgbọ́, alábùkún fún ni àwọn mi, wọ́n gbàgbọ́!"

30 ̀pọ̀lọpọ̀ iṣẹ́ àmì mìíràn ni Jesu ṣe níwájú àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, a kọ sínú ìwé yìí. 31 Ṣùgbọ́n wọ̀nyí ni a kọ, ̀yin gbàgbọ́ Jesu í ṣe Kristi náà, Ọmọ Ọlọ́run, àti nípa gbígbàgbọ́, ̀yin ìyè orúkọ rẹ̀.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-