Publicidade

João 9

Jesu la ojú ẹni a afọ́

1 ó ti ń kọjá lọ, ó ọkùnrin kan ó fọ́láti ìgbà ìbí rẹ̀ . 2 Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ bi í léèrè, , "Rabbi, ta ó dẹ́ṣẹ̀, ọkùnrin yìí tàbí àwọn òbí rẹ̀, a fi i afọ́?"

3 Jesu dáhùn , "í ṣe nítorí ọkùnrin yìí dẹ́ṣẹ̀, tàbí àwọn òbí rẹ̀: ṣùgbọ́n a ba à fi iṣẹ́ Ọlọ́run hàn lára rẹ̀. 4 Èmi láti ṣe iṣẹ́ ẹni ó rán mi, níwọ̀n ìgbà ó ti jẹ́ ̀sán, òru ń bọ̀ nígbà ẹnìkan yóò ṣe iṣẹ́. 5 Níwọ́n ìgbà mo láààyè, èmi ni ìmọ́lẹ̀ ayé."

6 Nígbà ó ti bẹ́̀ tan, ó tutọ́ sílẹ̀, ó fi itọ́ náà ṣe amọ̀, ó fi amọ̀ náà ra ojú afọ́náà. 7 Ó fún un , "Lọ wẹ̀ nínú adágún Siloamu!" (Ìtumọ̀ ̀rọ̀ yìí ni "rán"). Nítorí náà ó gba ̀rẹ̀ lọ, ó wẹ̀, ó , ó ń ríran.

8 Ǹjẹ́ àwọn aládùúgbò àti àwọn ó i nígbà àtijọ́ alágbe ni ó jẹ́, , "Ẹni ó ti ń jókòó ṣagbe kọ́ yìí?" 9 Àwọn kan òun ni.

Àwọn ẹlòmíràn , "Bẹ́̀ kọ́, ó jọ ́ ni."

Ṣùgbọ́n òun , "Èmi ni."

10 Nígbà náà ni wọ́n fún un , "wo ni ojú rẹ ṣe ?"

11 Ó dáhùn ó fún un , "Ọkùnrin kan a ń Jesu ni ó ṣe amọ̀, ó fi kun ojú , ó fún mi , Lọ adágún Siloamu, o wẹ̀, èmi lọ, mo wẹ̀, mo ríran."

12 Wọ́n fún un , "Òun náà ha ?"

Ó , "Èmi mọ̀."

Àwọn Farisi wádìí ìwòsàn

13 Wọ́n ẹni ojú rẹ̀ ti fọ́ sọ́dọ̀ àwọn Farisi. 14 Ọjọ́ ìsinmi ni ọjọ́ náà nígbà Jesu ṣe amọ̀, ó á lójú. 15 Nítorí náà àwọn Farisi pẹ̀tún bi í léèrè, ó ti ṣe ríran. Ọkùnrin náà fèsì, "Ó fi amọ̀ ojú mi, mo wẹ̀, báyìí mo ríran."

16 Nítorí náà àwọn kan nínú àwọn Farisi , "Ọkùnrin yìí ti ̀dọ̀ Ọlọ́run , nítorí pa ọjọ́ ìsinmi mọ́."

Àwọn ẹlòmíràn , "Ọkùnrin í ṣe ẹlẹ́ṣẹ̀ yóò ha ti ṣe ṣe irú iṣẹ́ àmì wọ̀nyí?" Ìyapa láàrín wọn.

17 Nítorí náà, wọ́n tún fún afọ́náà , "ni ìwọ nípa rẹ̀, nítorí ó ́ lójú?"

Ó , "Wòlíì í ṣe."

18 Nítorí náà àwọn Júù gbàgbọ́ nípa rẹ̀ ojú rẹ̀ ti fọ́ , àti ó tún ríran, títí wọ́n fi pe àwọn òbí ẹni a ti lójú. 19 Wọ́n bi wọ́n léèrè , "Ǹjẹ́ èyí ni ọmọ yín, ẹni ̀yin , a afọ́? Báwo ni ó ṣe ríran nísinsin yìí?"

20 Àwọn òbí rẹ̀ wọn lóhùn , "Àwa mọ̀ ọmọ wa ni èyí, àti a i afọ́, 21 ṣùgbọ́n ó ṣe ń ríran nísinsin yìí àwa mọ̀, ẹni ó á lójú, àwa mọ̀, ẹni ó ti dàgbà ni òun; bi í léèrè, yóò fúnra rẹ̀." 22 Nǹkan wọ̀nyí ni àwọn òbí rẹ̀ sọ, nítorí wọ́n bẹ̀àwọn Júù: nítorí àwọn Júù ti fohùn ṣọ̀kan ẹnìkan jẹ́wọ́ Kristi ni, wọn ó yọ ́ kúrò nínú Sinagọgu. 23 Nítorí èyí ni àwọn òbí rẹ̀ fi , "Ẹni ó dàgbà ni òun, bi í léèrè."

24 Nítorí náà, wọ́n pe ọkùnrin afọ́náà lẹ́̀kejì, wọ́n fún un , "Fi ògo fún Ọlọ́run, àwa mọ̀ ẹlẹ́ṣẹ̀ ni ọkùnrin yìí jẹ́."

25 Nítorí náà, ó dáhùn ó , "ẹlẹ́ṣẹ̀ ni, èmi mọ̀, Ohun kan ni mo mọ̀, mo fọ́, nísinsin yìí mo ríran."

26 Nítorí náà, wọ́n fún un , "ni ó ṣe ́? Báwo ni ó ṣe ́ lójú."

27 Ó wọn lóhùn , "Èmi ti sọ fún yín tẹ́lẹ̀, ̀yin gbọ́, nítorí kín ni ̀yin ṣe ń fẹ́ tún gbọ́? ̀yin pẹ̀ń fẹ́ ṣe ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ ?"

28 Wọ́n fi í ṣe ẹlẹ́, wọ́n , "Ìwọ ni ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, ṣùgbọ́n ọmọ-ẹ̀yìn Mose ni àwa. 29 Àwa mọ̀ Ọlọ́run Mose sọ̀rọ̀, ṣùgbọ́n ó ṣe ti eléyìí, àwa mọ ibi ó ti ."

30 Ọkùnrin náà dáhùn ó fún wọn , "Ohun ìyanu à ni èyí, ̀yin mọ ibi ó , ṣùgbọ́n òun à ti lójú. 31 Àwa mọ̀ Ọlọ́run í gbọ́ ti ẹlẹ́ṣẹ̀; ṣùgbọ́n ẹnìkan ṣe olùfọkànsìn Ọlọ́run, ó ń ṣe ìfẹ́ rẹ̀, Òun ni ó ń gbọ́ tirẹ̀. 32 Láti ìgbà ayé ti ṣẹ̀, a ì ì gbọ́ ẹnìkan la ojú ẹni a afọ́. 33 Ìbá ṣe ọkùnrin yìí ti ̀dọ̀ Ọlọ́run , ṣe ohunkóhun."

34 èyí, wọ́n fèsì , "Láti ìbí ni o jíngírí nínú ̀ṣẹ̀, ìwọ ha fẹ́ kọ́ wa ?" Wọ́n í sóde.

Ìfọ́̀

35 Jesu gbọ́ , wọ́n ti í sóde; nígbà ó i, ó pe, "Ìwọ gba Ọmọ Ọlọ́run, gbọ́ ?"

36 Òun dáhùn , "Ta ni, Olúwa, èmi gbà á gbọ́?"

37 Jesu fún un , "Ìwọ ti i, Òun náà ni ẹni ń sọ̀rọ̀ yìí."

38 Ó , "Olúwa, mo gbàgbọ́," ó wólẹ̀ fún un.

39 Jesu , "Nítorí ìdájọ́ ni mo ṣe ayé yìí, àwọn ríran ríran; àti àwọn ó ríran di afọ́."

40 Nínú àwọn Farisi ó lọ́dọ̀ rẹ̀ gbọ́ nǹkan wọ̀nyí, wọ́n fún un , "Àwa pẹ̀fọ́?"

41 Jesu fún wọn , "Ìbá ṣe ̀yin fọ́, ̀yin lẹ́sẹ̀, ṣùgbọ́n nísinsin yìí ̀yin , Àwa ríran,nítorí náà ̀ṣẹ̀ yín síbẹ̀.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-