Publicidade

Marcos 11

Jesu fi ̀yẹ wọ Jerusalẹmu bi ọba

1 11.1-10: Mt 21.1-9; Lk 19.29-38. wọ́n ti súnmọ́ Betfage àti Betani ̀yìn odi ìlú Jerusalẹmu, wọ́n orí òkè olifi. Jesu rán méjì nínú àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ síwájú. 2 Ó pàṣẹ fún wọn , "lọ abúlé lọ́hùn ún . Nígbà wọlé, ̀yin yóò ọmọ kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ a so mọ́lẹ̀ ẹnikẹ́ni ì i gùn . u, ibi yìí. 3 ẹnikẹ́ni bi yín , fi ń ṣe èyí?sọ fún un , Olúwa í fi ṣe, yóò a padà síbí láìpẹ́.’ "

4 11.4: Mk 14.16. Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn méjì náà lọ ó ti rán wọn. Wọ́n ọmọ kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ náà a so ẹnu-ọ̀lóde ìta gbangba, wọ́n u. 5 wọ́n ti ń u, díẹ̀ nínú àwọn ó dúró níbẹ̀ bi wọ́n léèrè , "Ki ni ẹyin n ṣe, ̀yin fi ń ọmọ kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ n ?" 6 Wọ́n fún wọn gẹ́gẹ́ Jesu ti wọ́n sọ, wọ́n jọ̀wọ́ wọn lọ́wọ́ lọ. 7 11.7-10: Jh 12.12-15.Wọ́n fa ọmọ kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ náà tọ Jesu . Wọ́n tẹ́ aṣọ wọn ̀yìn rẹ̀, òun jókòó lórí rẹ̀. 8 Àwọn púpọ̀ tẹ́ aṣọ wọn ̀. Àwọn mìíràn ṣẹ́ ̀ka igi, wọ́n fọ́n wọn ̀. 9 11.9: Sm 118.26; Mt 21.15; 23.39.Àti àwọn ń lọ níwájú, àti àwọn ń bọ̀ lẹ́yìn, gbogbo wọn ń kígbe ,

"Hosana!"

"Olùbùkún ni ẹni náà ó ń bọ̀ orúkọ Olúwa!"

10 "Olùbùkún ni fún ìjọba ń bọ̀ , ìjọba Dafidi, baba wa!"

"Hosana lókè ̀run!"

11 11.11: Mt 21.10-11,17. Jesu wọ Jerusalẹmu ó lọ inú tẹmpili. Ó wo ohun gbogbo yíká fínní fínní. Ó kúrò níbẹ̀, nítorí ilẹ̀ ti ṣú. Ó padà lọ Betani pẹ̀àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ méjìlá.

Jesu palẹ̀ tẹmpili mọ́

12 11.12-14: Mt 21.18-19; Lk 13.6-9. òwúrọ̀ ọjọ́ kejì, wọ́n ti kúrò Betani, ebi ń pa Jesu. 13 Ó igi ̀pọ̀tọ́ kan lọ́̀́kán ewé kún orí rẹ̀. Nígbà náà, ó lọ ìdí rẹ̀ láti ó bóyá ó léso tàbí léso. Nígbà ó ibẹ̀, ewé lásán ni ó , èso lórí rẹ̀. Nítorí àkókò náà í ṣe àkókò igi ̀pọ̀tọ́ máa ń so. 14 Lẹ́yìn náà, Jesu pàṣẹ fún igi náà , "ẹnikẹ́ni ṣe jẹ èso lórí rẹ mọ́ títí láé." Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ gbọ́ nígbà ó bẹ́̀.

15 11.15-18: Mt 21.12-16; Lk 19.45-48; Jh 2.13-16. Nígbà ti wọ́n padà Jerusalẹmu, ó wọ inú tẹmpili. Ó bẹ̀rẹ̀ nílé àwọn oníṣòwò àti àwọn oníbàárà wọn síta. Ó ti tábìlì àwọn ń pààrọ̀ owó nínú tẹmpili ṣubú. Bákan náà ni ó ti ìjókòó àwọn ń ta ẹyẹlé lulẹ̀. 16 gba ẹnikẹ́ni láààyè láti gbé ẹrù ọjà títà gba inú tẹmpili wọlé. 17 11.17: Isa 56.7; Jr 7.11.Gẹ́gẹ́ ó ti kọ́ wọn, ó , "Ṣé a ti kọ ́ : Ilé àdúrà ni a o máa pe ilé mi, gbogbo orílẹ̀-èdè?Ṣùgbọ́n ̀yin ti sọ ́ di ibùgbé àwọn ọlọ́ṣà."

18 Nígbà àwọn olórí àlùfáà àti àwọn olùkọ́ òfin gbọ́ ohun ó ti ṣe, wọ́n bẹ̀rẹ̀ ń gbà èrò wọn yóò ti ṣe pa á. Wọ́n bẹ̀rògbòdìyàn yóò bẹ́ sílẹ̀, nítorí àwọn ènìyàn ìgbóná ọkàn ̀kọ́ rẹ̀.

19 11.19: Lk 21.37. ìrọ̀lẹ́ ọjọ́ náà, ìṣe wọn, Jesu àti àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ jáde kúrò ìlú Jerusalẹmu.

Igi ̀pọ̀tọ́ eṣo

20 11.20-25: Mt 21.20-22; Mt 17.20; Lk 17.6. òwúrọ̀ ọjọ́ kejì, wọ́n ti ń kọjá lọ, wọ́n igi ̀pọ̀tọ́ Jesu fi . Wọ́n i ó ti gbẹ tigbòǹgbò tigbòǹgbò. 21 Peteru rántí Jesu ti igi náà . Nígbà náà ni ó sọ fún Jesu , "Rabbi, ó! Igi ̀pọ̀tọ́ ìwọ fi ti gbẹ!"

22 Jesu dáhùn , "ìgbàgbọ́ nínú Ọlọ́run. 23 Lóòótọ́ ni fún un yín, ẹnikẹ́ni fún òkè Ṣídìí, gbé ara rẹ sọ sínú Òkun,ti ṣe iyèméjì nínú ọkàn rẹ̀ ṣùgbọ́n ó gbàgbọ́ ohun òun yóò ṣẹ, yóò bẹ́̀ fún un. 24 11.24: Jh 14.13-14; 16.23; Mt 7.7-11.Torí náà, mo fún yín ohunkóhun béèrè fún nínú àdúrà, ìgbàgbọ́ , ó tẹ̀ yín lọ́wọ́, yóò jẹ́ tiyín. 25 11.25: Mt 6.14-15; 18.35.Nígbà ń gbàdúrà, kọ́kọ́ dáríjì, ̀yin ohunkóhun ẹnikẹ́ni, baba yín ń bẹ ̀run à le dárí àwọn ̀ṣẹ̀ tiyín náà yín."11.25 Àwọn àkọsílẹ̀ àtijọ́ ìwé Marku kan se àfikún ọ̀rọ̀ yìí yín. 26 Ṣùgbọ́n bí ẹ̀yin bá kọ̀ láti dárí ẹ̀ṣẹ̀ àwọn ènìyàn jì wọ́n, baba yín kò ní í dárí ẹ̀ṣẹ̀ yín jì yín.

27 11.27-33: Mt 21.23-27; Lk 20.1-8; Jh 2.18. Lẹ́yìn èyí, wọ́n tún padà Jerusalẹmu.

Ìbéèrè àṣẹ Jesu

Jesu ti ń rìn kiri ni tẹmpili, àwọn olórí àlùfáà àti àwọn olùkọ́ òfin pẹ̀àwọn àgbàgbà Júù sọ́dọ̀ rẹ̀. 28 Wọ́n béèrè lọ́wọ́ rẹ̀ , "Àṣẹ wo ni ó fi ń ṣe nǹkan yìí? Ta ni ó fún ni àṣẹ yìí láti máa ṣe nǹkan wọ̀nyí?"

29 Jesu wọn lóhùn , "Èmi yóò bi yín léèrè ̀rọ̀ kan, mi lóhùn, èmi yóò sọ fún yín àṣẹ èmi fi ń ṣe nǹkan wọ̀nyí." 30 Ìtẹ̀bọmi Johanu láti ̀run wa ni, tàbí láti ̀dọ̀ ènìyàn? "mi lóhùn!"

31 Wọ́n ara wọn jíròrò , "a , Láti ̀run ni,òun ó , Nígbà mọ̀ bẹ́̀, èéṣe fi gbà à gbọ́?’ 32 Ṣùgbọ́n a , àti ̀dọ̀ ènìyàn, wọ́n bẹ̀àwọn ènìyàn, nítorí gbogbo ènìyàn gbàgbọ́ wòlíì gidi ni Johanu."

33 Nítorí náà, wọ́n kọjú Jesu wọn dáhùn , "Àwa mọ̀."

Nígbà náà ni Jesu , "Níwọ́n ìgbà dáhùn ìbéèrè mi, Èmi náà yóò sọ fún yín àṣẹ mo fi ń ṣe nǹkan wọ̀nyí."

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_23-13-58-