Publicidade

Marcos 15

Jesu jẹ́jọ́ níwájú Pilatu

1 kùtùkùtù òwúrọ̀, àwọn olórí àlùfáà, àwọn àgbàgbà, àwọn olùkọ́ òfin àti gbogbo àjọ ìgbìmọ̀ fi ẹnu lórí ohun wọn yóò ṣe. Wọ́n de Jesu, wọ́n un lọ, wọ́n fi Pilatu lọ́wọ́.

2 Pilatu bi í léèrè, ó ni, "Ṣe ìwọ ni ọba àwọn Júù?"

Jesu dáhùn , "Gẹ́gẹ́ bi ìwọ ti náà ni."

3 Àwọn olórí àlùfáà fi ̀sùn ohun púpọ̀ kàn án. 4 Pilatu tún bi í léèrè , "Ṣe ìwọ dáhùn ni? Wo gbogbo ̀sùn wọ́n fi kàn ."

5 Ṣùgbọ́n Jesu dalóhùn síbẹ̀, bẹ́̀ ti ẹnu fi ya Pilatu.

6 báyìí, nígbà àjọ, gẹ́gẹ́ àṣà, òun a máa òǹdè kan sílẹ̀ fún wọn, ẹnikẹ́ni wọ́n béèrè fún. 7 Ọkùnrin kan orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Baraba. Wọ́n ti ju òun àti àwọn ọlọ̀tẹ̀ ẹgbẹ́ rẹ̀ ọgbà ̀wọ̀n, nítorí wọ́n ṣọ̀tẹ̀ ìjọba, wọ́n pa ènìyàn nínú ìdìtẹ̀ wọn. 8 ̀pọ̀ ènìyàn lọ Pilatu, wọ́n ó ṣe ó ti máa ń ṣe fún wọn ọdọọdún.

9 Pilatu béèrè lọ́wọ́ wọn , "Ṣe ̀yin ń fẹ́ èmi ọba àwọn Júù sílẹ̀ fún yin?" 10 Òun mọ̀ nítorí ìlara ni àwọn olórí àlùfáà ṣe Jesu òun lọ́wọ́. 11 Nígbà náà ni àwọn olórí àlùfáà ru ̀pọ̀ ènìyàn sókè , ó kúkú Baraba sílẹ̀ fún wọn.

12 Pilatu tún béèrè lọ́wọ́ wọn , "ni ̀yin ń fẹ́ èmi ó ṣe pẹ̀ẹni ti ̀yin n ọba àwọn Júù?"

13 Wọ́n tún kígbe sókè , "Kàn án mọ àgbélébùú!"

14 Nígbà náà ni Pilatu bi wọn léèrè , "Èéṣe? Búburú ni ó ṣe?"

Wọ́n kígbe sókè gidigidi , "Kàn án mọ́ àgbélébùú!"

15 Pilatu ń fẹ́ ṣe èyí ó wu àwọn ènìyàn, ó Baraba sílẹ̀ fún wọn. Nígbà ó na Jesu tan o á wọn lọ́wọ́ láti kàn an mọ́ àgbélébùú.

Àwọn ọmọ-ogun fi Jesu ṣe ẹlẹ́

16 Àwọn ọmọ-ogun á jáde lọ sínú ààfin (a ń Pretoriomu), wọ́n pe gbogbo ẹgbẹ́ àwọn ọmọ-ogun jọ. 17 Wọn fi aṣọ aláwọ̀ àlùkò wọ̀ ́, wọ́n hun adé ̀gún, wọ́n fi e orí. 18 Wọ́n bẹ̀rẹ̀ i ì , Kábíyèsí, ọba àwọn Júù. 19 Wọ́n fi ̀ú lórí, wọ́n tutọ́ i lára, wọ́n kúnlẹ̀ níwájú rẹ̀, wọ́n foríbalẹ̀ fún un. 20 Nígbà wọ́n fi ṣẹ̀sín tan, wọ́n bọ aṣọ elése àlùkò náà kúrò lára rẹ̀, wọ́n fi aṣọ rẹ̀ wọ̀ ́, wọ́n un jáde lọ láti kàn án mọ́ àgbélébùú.

Wọ́n kan Jesu mọ́ àgbélébùú

21 Wọ́n ọkùnrin kan ń kọjá lọ. Simoni ará Kirene. Òun ni baba Aleksanderu àti Rufusi. Wọ́n un tipátipá , ó àgbélébùú Jesu. 22 Wọ́n Jesu Gọlgọta (èyí ìtumọ̀ rẹ̀ ń jẹ́ Ibi Agbárí) 23 Wọ́n fi myrri wáìnì a dàpọ̀ mọ́ òjìá fún un mu, ṣùgbọ́n òun gbà á. 24 Wọ́n kàn án mọ́ àgbélébùú. Wọ́n pín aṣọ rẹ̀ láàrín ara wọn, wọ́n dìbò lórí àwọn aṣọ náà ni wọn à mọ èyí yóò jẹ́ ti olúkúlùkù.

25 wákàtí kẹta ọjọ́ ni wọ́n kàn án mọ́ àgbélébùú. 26 Àkọlé ìfisùn wọ́n kọ sókè orí rẹ̀ ni:

Ọba àwọn Júù.

27 Wọ́n kan àwọn olè méjì mọ́ àgbélébùú pẹ̀rẹ̀, ̀kan lọ́wọ́ ̀tún rẹ̀, èkejì lọ́wọ́ òsì rẹ̀. 29 Àwọn ń kọjá lọ ń fi ṣe ẹlẹ́, wọ́n ń mi orí wọn pẹ̀, wọ́n , "Háà! Ìwọ yóò tẹmpili yóò tún un kọ́ láàrín ọjọ́ mẹ́ta, 30 sọ̀kalẹ̀ láti orí àgbélébùú , o gba ara rẹ !" 31 Bákan náà ni àwọn olórí àlùfáà àti àwọn olùkọ́ òfin fi í ṣẹ̀sín láàrín ara wọn, wọ́n , "Ó gba àwọn ẹlòmíràn ṣùgbọ́n, ara rẹ̀ ni gbàlà. 32 Jẹ́ Kristi, ọba Israẹli, sọ̀kalẹ̀ láti orí igi àgbélébùú nísinsin yìí àwa ó i, àwa ó gbàgbọ́." Bákan náà, àwọn ti a kàn mọ́ àgbélébùú pẹ̀rẹ̀ ń kẹ́gàn rẹ̀.

Ikú Jesu

33 Nígbà ó di wákàtí kẹfà, òkùnkùn bo gbogbo ilẹ̀ títí di wákàtí kẹsànán. 34 wákàtí kẹsànán ni Jesu kígbe sókè ohùn rara, ó , "Eli, Eli, lama sabakitani?" (ìtumọ̀ èyí í ṣe, "Ọlọ́run mi, Ọlọ́run mi, èéṣe ìwọ fi kọ̀ sílẹ̀?").

35 Nígbà àwọn kan nínú àwọn wọ́n dúró níbẹ̀ gbọ́, wọ́n , "ó ó ń pe Elijah."

36 Nígbà náà ni ẹnìkan sáré lọ ki kànìnkànìn bọ inú ọtí kíkan, ó fi orí ̀, ó án Jesu ó mu ún. Ó , "jẹ́ a máa ó, bóyá Elijah yóò sọ̀ ́ kalẹ̀ wa."

37 Jesu tún kígbe sókè ni ohùn rara, ó jọ̀wọ́ ̀rẹ̀ lọ́wọ́.

38 Aṣọ ìkélé tẹmpili fàya méjì láti òkè ìsàlẹ̀. 39 Nígbà balógun ̀rún ó dúró lẹ́gbẹ̀ ̀dọ̀ Jesu i ó kígbe sókè báyìí, ó jọ̀wọ́ èmí rẹ̀ lọ́wọ́, ó , "Lóòótọ́ Ọmọ Ọlọ́run ni ọkùnrin yìí í ṣe."

40 Àwọn obìnrin kan níbẹ̀ pẹ̀, wọ́n ń ó láti òkèèrè. Maria Magdalene lára àwọn obìnrin náà, àti Maria ìyá Jakọbu kékeré àti ti Jose, àti Salome. 41 Àwọn wọ̀nyí, nígbà ó Galili máa ń tọ̀ ́ lẹ́yìn, wọ́n a máa ṣe ìránṣẹ́ fún un àti ̀pọ̀ obìnrin mìíràn wọ́n a gòkè Jerusalẹmu.

Ìsìnkú Jesu

42 Ọjọ́ yìí jẹ́ ọjọ́ ìpalẹ̀mọ́ (èyí i ṣe, ọjọ́ ṣáájú ọjọ́ ìsinmi). Nígbà ilẹ̀ ọjọ́ náà ṣú, 43 Josẹfu ará Arimatea , ̀kan pàtàkì nínú àwọn ọmọ ìgbìmọ̀, ẹni ń retí ìjọba Ọlọ́run, ó fi ìgboyà lọ iwájú Pilatu láti tọrọ òkú Jesu. 44 Ẹnu ya Pilatu láti gbọ́ Jesu ti . Nítorí náà ó pe balógun ̀rún, ó i léèrè bóyá Jesu ti nítòótọ́. 45 Nígbà balógun ̀rún náà fún Pilatu ni ìdánilójú Jesu ti , Pilatu jọ̀wọ́ òkú rẹ̀ fún Josẹfu. 46 Josẹfu ti ra aṣọ ̀gbọ̀ . Ó sọ òkú Jesu kalẹ̀: ó fi aṣọ ̀gbọ̀ náà í. Ó tẹ́ inú ibojì, wọ́n gbẹ́ ara àpáta. Ó òkúta ẹnu ibojì náà. 47 Maria Magdalene àti Maria ìyá Jose ń ó bi Josẹfu ti n tẹ́ Jesu ibojì.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-