Publicidade

Marcos 8

Jesu bọ́ ẹgbàajì (4,000) ènìyàn

1 8.1-10: Mt 15.32-39; Mk 6.32-44; Mt 14.13-21; Lk 9.11-17; Jh 6.5-13. ọjọ́ kan, ̀pọ̀ ènìyàn ti péjọ, oúnjẹ fún wọn mọ́ láti jẹ. Jesu pe àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀. 2 Ó fún wọn , "Àánú ̀pọ̀ ènìyàn wọ̀nyí ṣe nítorí ó ọjọ́ mẹ́ta wọ́n ti níhìn-ín, ohun kan ó sílẹ̀ fún wọn láti jẹ. 3 mo sọ fún wọn láti máa lọ ilé wọn bẹ́̀ pẹ̀ebi, wọn yóò dákú lójú ̀, nítorí àwọn mìíràn nínú wọn ti ̀jíjìn ."

4 Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ béèrè , "Níbo ni a ó ti àkàrà ó láti fi bọ́ wọn nínú aṣálẹ̀ yìí?"

5 Jesu béèrè lọ́wọ́ wọn , "Ìṣù àkàrà mélòó lẹ lọ́wọ́?"

Wọ́n fèsì , "Ìṣù àkàrà méje."

6 Nítorí náà, ó pàṣẹ fún àwọn ènìyàn náà láti jókòó lórí ilẹ̀. Ó odindi àkàrà méje náà, ó dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọ́run, ó wọ́n wẹ́wẹ́, ó pín wọn fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ láti gbé ka iwájú àwọn ènìyàn, wọ́n ṣe bẹ́̀. 7 Wọ́n àwọn ẹja wẹ́wẹ́ díẹ̀ pẹ̀. Jesu tún dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọ́run fún ìpèsè náà, ó pàṣẹ fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ láti pín wọn fún àwọn ènìyàn náà. 8 Gbogbo ̀pọ̀ ènìyàn náà jẹ àjẹyó àti àjẹtẹ́rùn. Lẹ́yìn èyí wọ́n àjẹkù ti ó jọ, agbọ̀n méje kún. 9 Àwọn ó jẹ ́ ìwọ̀n ẹgbàajì (4,000) ènìyàn, ó rán wọn lọ. 10 Lẹ́sẹ̀kẹsẹ̀, lẹ́yìn èyí, Jesu wọ inú ọkọ̀ ojú omi pẹ̀àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, wọ́n gúnlẹ̀ agbègbè Dalmanuta.

11 8.11-12: Mt 16.1-4; 12.38-39; Lk 11.29. Àwọn Farisi tọ Jesu , wọ́n bẹ̀rẹ̀ béèrè ìbéèrè lọ́wọ́ rẹ̀. Láti dán an , wọ́n béèrè fún àmì láti ̀run. 12 Jesu kanlẹ̀, nígbà ó gbọ́ ìbéèrè wọn. Ó dáhùn , "Èéṣe ìran yìí fi ń àmì? Lóòótọ́ ni mo sọ fún un yín si àmì a ó fi fún ìran yín." 13 8.13-21: Mt 16.4-12.Nígbà náà ni ó padà sínú ọkọ̀ ojú omi ó fi àwọn ènìyàn sílẹ̀, ó rékọjá apá kejì Òkun náà.

Ìwúkàrà àwọn Farisi àti Herodu

14 Ṣùgbọ́n àwọn ọmọ-ẹ̀yìn ti gbàgbé láti àkàrà yóò wọn ́n jẹ lọ́wọ́. Ẹyọ ìṣù àkàrà kan ṣoṣo ni ó nínú ọkọ̀ wọn. 15 8.15: Lk 12.1; Mk 6.14; 12.13.wọ́n ti ń rékọjá, Jesu kìlọ̀ fún wọn , "máa ṣọ́ra nítorí ìwúkàrà àwọn Farisi àti ìwúkàrà Herodu."

16 Wọ́n bẹ̀rẹ̀ ronú èyí láàrín ara wọn , "Torí a àkàrà lọ́wọ́ ni?"

17 8.17: Mk 6.52; Jr 5.21; Isa 6.9-10; Mt 13.10-15. Jesu mọ ohun wọ́n sọ láàrín ara wọn, ó wọn lóhùn , "Èéṣe ti ̀yin fi ń ṣe àròyé ̀yin àkàrà lọ́wọ́? ̀yin kíyèsi i títí di ìsinsin yìí, ti mòye, àbí ọkàn yín le ni. 18 ̀yin ojú, fi ríran? ̀yin ni etí gbọ́ran? ̀yin rántí? 19 8.19: Mk 6.41-44.Nígbà ti mo bu ìṣù àkàrà márùn-ún fún ẹgbẹ̀rún márùn-ún (5,000) ènìyàn, agbọ̀n mélòó ni ó kún fún àjẹkù ṣàjọ?"

Wọ́n , "Méjìlá."

20 8.20: Mk 8.1-10. "Bákan náà, nígbà mo bọ́ ẹgbàajì (4,000) pẹ̀ìṣù àkàrà méje, agbọ̀n mélòó sílẹ̀ lẹ́yìn àjẹyó àti àjẹtẹ́rùn wọn?"

Wọ́n dáhùn , "Ó ku ̀kún agbọ̀n méje."

21 Ó fún wọn , "Èéha ti ṣe fi yin?"

Ìwòsàn ọkùnrin afọ́Betisaida

22 8.22-26: Mk 10.46-52; Jh 9.1-7. 8.22: Mk 6.45; Lk 9.10. Nígbà wọ́n Betisaida, àwọn ènìyàn kan afọ́kan sọ́dọ̀ rẹ̀. Wọ́n bẹ̀ ́ ó fi ọwọ́ kàn án, ó ó sàn. 23 8.23: Mk 7.33; 5.23.Jesu fa ọkùnrin náà lọ́wọ́, ó un jáde lọ ̀yìn ìlú. Ó tu itọ́ i lójú. Ó gbé ọwọ́ rẹ̀ ojú náà. Ó bi í léèrè , "Ǹjẹ́ ìwọ ohunkóhun nísinsin yìí?"

24 Ọkùnrin náà wo àyíká rẹ̀, ó dáhùn , "Bẹ́̀ ni Olúwa, mo àwọn ènìyàn, ṣùgbọ́n n wọn kedere, wọ́n n rìn kiri àgékù igi."

25 Nígbà náà, Jesu tún gbé ọwọ́ rẹ̀ méjèèjì àwọn ojú ọkùnrin náà, ọkùnrin náà ti ranjú mọ́ ọn, a ìran rẹ̀ padà, ó gbogbo nǹkan kedere. 26 Jesu rán an àwọn ẹbí rẹ̀. Ó kìlọ̀ fún un , "ṣe lọ ìlú, o sọ fún ẹnikẹ́ni ìlú."

Peteru jẹ́wọ́ ẹni Kristi jẹ́

27 8.27-30: Mt 16.13-20; Lk 9.18-21; Jh 6.66-69. Nísinsin yìí, Jesu àti àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ kúrò Galili. Wọ́n jáde lọ àwọn abúlé agbègbè Kesarea-Filipi. wọ́n ti ń lọ lọ́, ó béèrè lọ́wọ́ wọn , "Ta ni àwọn ènìyàn ń fi ?"

28 8.28: Mk 6.14. Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn náà dáhùn , "Àwọn kan ìwọ ni Johanu Onítẹ̀bọmi, àwọn mìíràn sọ , ìwọ ni Elijah tàbí àwọn wòlíì mìíràn ni ó tún padà sáyé."

29 Ó bi wọ́n , "Ta ni ̀yin ń fi ?"

Peteru dáhùn , "Ìwọ ni Kristi náà."

30 8.30: Mk 9.9; 1.34. Ṣùgbọ́n Jesu kìlọ̀ fún wọn, wọn sọ èyí fún ẹnikẹ́ni.

Jesu sọ àsọtẹ́lẹ̀ nípa ikú ara rẹ̀

31 8.31–9.1: Mt 16.21-28; Lk 9.22-27. Ó bẹ̀rẹ̀ kọ́ wọn, , Ọmọ Ènìyàn le ṣàìmá jìyà ohun púpọ̀, a ó kọ̀ ́ sílẹ̀ láti ọwọ́ àwọn àgbàgbà, àwọn olórí àlùfáà àti àwọn olùkọ́ òfin, a ó pa á, lẹ́yìn ọjọ́ mẹ́ta yóò jíǹde. 32 Jesu wọn sọ̀rọ̀ yìí, láìfi ohunkóhun pamọ́ fún wọn, ṣùgbọ́n Peteru pe Jesu sẹ́yìn, ó bẹ̀rẹ̀ si a .

33 8.33: Mt 4.10. Jesu yípadà, ó wo àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀. Ó fún Peteru pẹ̀ìtara , "Kúrò lẹ́yìn mi Satani, nítorí ìwọ ro ohun Ọlọ́run ṣe ohun ènìyàn."

̀àgbélébùú

34 8.34: Mt 10.38; Lk 14.27. Nígbà náà ni Jesu pe àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ àti ̀pọ̀ ènìyàn láti wọn sọ̀rọ̀, ó fún wọn , "ẹnikẹ́ni fẹ́ tọ̀ lẹ́yìn, ó sẹ́ ara rẹ̀, ó si gbé àgbélébùú rẹ̀, ó si máa tọ̀ mi lẹ́yìn. 35 8.35: Mt 10.39; Lk 17.33; Jh 12.25.Nítorí ẹni gbìyànjú láti gba ̀ara rẹ̀ , yóò sọ ́ . Iye àwọn ó sọ ̀wọn nìkan nítorí í tèmi àti nítorí ìyìnrere, òun náà ni yóò gbà á . 36 Nítorí èrè ni ó jẹ́ fún ẹni ó jèrè gbogbo ayé, ó sọ ̀rẹ̀ ? 37 Tàbí ni ènìyàn yóò fi ṣe pàṣípàrọ̀ ̀rẹ̀? 38 8.38: Mt 10.33; Lk 12.9.Nítorí náà, ẹnikẹ́ni tijú àti gbà tàbí ̀rọ̀ mi nínú ìran panṣágà àti ẹlẹ́ṣẹ̀ yìí, ó kún fún àìgbàgbọ́ àti ̀ṣẹ̀ báyìí, Ọmọ Ènìyàn yóò tijú rẹ̀ nígbà ó padà nínú ògo Baba rẹ̀, pẹ̀àwọn angẹli mímọ́."

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_21-26-40-