Publicidade

Mateus 22

Òwe àsè ìgbéyàwó

1 Jesu tún fi òwe sọ̀rọ̀ fún wọn : 2 "Ìjọba ̀run dàbí ọba kan ti ó múra àsè ìgbéyàwó ńlá fún ọmọ rẹ̀ ọkùnrin. 3 Ó rán àwọn ọmọ ̀dọ̀ rẹ̀ lọ pe àwọn a ti tẹ́lẹ̀ ibi àsè ìgbéyàwó. Ṣùgbọ́n wọn fẹ́ .

4 "Lẹ́yìn náà ó tún rán àwọn ọmọ ̀dọ̀ mìíràn , sọ fún àwọn mo ti , mo ti ṣe àsè náà tán. A pa màlúù àti ẹran àbọ́pa mi, a ti ṣe ohun gbogbo tán, wa ibi àsè ìgbéyàwó.

5 "Ṣùgbọ́n àwọn wọ̀n-ọn-nì ó ránṣẹ́ lọ á si. Wọ́n ń iṣẹ́ wọn lọ, ̀kan ̀oko rẹ̀, òmíràn ibi òwò rẹ̀." 6 Àwọn ìyókù àwọn ọmọ ̀dọ̀ rẹ̀, wọ́n ṣe àbùkù wọn, wọ́n wọ́n pa. 7 Ọba yìí bínú gidigidi, ó rán àwọn ọmọ-ogun rẹ̀, ó pa àwọn apànìyàn náà run, ó ìlú wọn.

8 "Nígbà náà ni ó fún àwọn ọmọ ̀dọ̀ rẹ̀ , Àsè ìgbéyàwó ti ṣe tàn, ṣùgbọ́n àwọn a yẹ fún ọlá náà. 9 lọ ìgboro àti òpópónà pe ẹnikẹ́ni àsè ìgbéyàwó náà. 10 Nítorí náà, àwọn ọmọ ̀dọ̀ náà jáde lọ òpópónà. Wọ́n oríṣìíríṣìí ènìyàn wọ́n , àwọn ò dára àti àwọn dára, ilé àsè ìyàwó kún fún àlejò.

11 "Ṣùgbọ́n nígbà ọba wọlé láti wo àwọn àlejò a , ó ọkùnrin kan nínú wọn wọ aṣọ ìgbéyàwó. 12 Ọba bi í , ̀rẹ́, báwo ni ìwọ ṣe níhìn-ín yìí láìní aṣọ ìgbéyàwó?Ṣùgbọ́n ọkùnrin náà ìdáhùn kankan.

13 "Nígbà náà ni ọba fún àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ , í tọwọ́ tẹsẹ̀, sọ ́ sínú òkùnkùn lóde níbi ẹkún àti ìpayínkeke .

14 "Nítorí ̀pọ̀ ni a ṣùgbọ́n díẹ̀ ni a yàn."

Sísan owó orí fún Kesari

15 Nígbà náà ni àwọn Farisi péjọpọ̀ láti ronú ̀wọn yóò gbà fi ̀rọ̀ ẹnu un. 16 Wọ́n rán àwọn ọmọ-ẹ̀yìn wọn pẹ̀àwọn ọmọ-ẹ̀yìn Herodu lọ sọ́dọ̀ rẹ̀ , "Olùkọ́, àwa mọ̀ olóòtítọ́ ni ìwọ, ìwọ ń kọ́ni ̀Ọlọ́run òtítọ́. Bẹ́̀ ni ìwọ í wo ojú ẹnikẹ́ni; nítorí ìwọ í ṣe ojúsàájú ènìyàn. 17 Nísinsin yìí sọ fún wa, ni èrò rẹ? Ǹjẹ́ ó tọ́ láti san owó orí fún Kesari tàbí tọ́?"

18 Ṣùgbọ́n Jesu ti mọ èrò búburú inú wọn, ó , "̀yin àgàbàgebè, èéṣe ti ̀yin fi ń dán mi ? 19 fi owó ẹyọ a fi ń san owó orí kan hàn mi." Wọn dínárì kan fún un, 20 ó bi wọ́n , "Àwòrán ta ni èyí? Àkọlé ?"

21 Wọ́n dáhùn , "Ti Kesari ni."

"Nígbà náà ni ó fún wọn ," "fi èyí í ṣe ti Kesari fún Kesari, fi èyí ti ṣe ti Ọlọ́run fún Ọlọ́run."

22 Nígbà wọ́n gbọ́ èyí, ẹnu wọ́n. Wọ́n fi í sílẹ̀, wọ́n tiwọn lọ.

Ìgbéyàwó nígbà àjíǹde

23 Ṣùgbọ́n ọjọ́ kan náà, àwọn Sadusi wọ́n sọ si àjíǹde lẹ́yìn ikú tọ Jesu láti bi í ìbéèrè, 24 wọ́n , "Olùkọ́, Mose fún wa , ọkùnrin kan àìlọ́mọ, arákùnrin rẹ̀ ṣú aya rẹ̀ lópó, ó ọmọ fún un. 25 ó jẹ́ bẹ́̀, láàrín wa níhìn-ín yìí, ìdílé kan ó arákùnrin méje. Èyí èkínní nínú wọn gbéyàwó, lẹ́yìn náà ó àìlọ́mọ. Nítorí náà ìyàwó rẹ̀ di ìyàwó arákùnrin kejì. 26 Bẹ́̀ gẹ́gẹ́ arákùnrin èkejì náà tún láìlọ́mọ. A fi ìyàwó rẹ̀ fún arákùnrin ó tún tẹ̀e. Bẹ́̀ ni títí òun fi di ìyàwó ẹni keje. 27 Níkẹyìn obìnrin náà pàápàá . 28 Nítorí ó ti ṣe ìyàwó àwọn arákùnrin méjèèje, ìyàwó ta ni yóò jẹ́ àjíǹde òkú?"

29 Ṣùgbọ́n Jesu wọn lóhùn , "Àìmọ̀kan yín ni ó fa irú ìbéèrè báyìí. Nítorí ̀yin mọ Ìwé Mímọ́ àti agbára Ọlọ́run. 30 Nítorí àjíǹde ìgbéyàwó, a fi í fún ni ìyàwó. Gbogbo ènìyàn yóò dàbí àwọn angẹli ̀run. 31 Ṣùgbọ́n nísinsin yìí, nípa ti àjíǹde òkú, tàbí ̀yin mọ̀ Ọlọ́run ń yín sọ̀rọ̀ nígbà ti ó : 32 Èmi ni Ọlọ́run Abrahamu, Ọlọ́run Isaaki, àti Ọlọ́run Jakọbu.Ọlọ́run í ṣe Ọlọ́run òkú, ṣùgbọ́n àwọn alààyè."

33 Nígbà ti àwọn ènìyàn gbọ́ èyí ẹnu wọ́n ̀kọ́ rẹ.

Òfin ó ga jùlọ

34 Nígbà ti wọ́n gbọ́ ó ti pa àwọn Sadusi lẹ́nu mọ́, àwọn Farisi ara wọn jọ. 35 ̀kan nínú wọn ṣe amòfin dán an pẹ̀ìbéèrè yìí. 36 Ó , "Olùkọ́ èwo ni ó ga jùlọ nínú àwọn òfin?"

37 Jesu dáhùn , " Fẹ́ Olúwa Ọlọ́run rẹ pẹ̀gbogbo ọkàn rẹ, gbogbo ̀rẹ àti gbogbo inú rẹ.38 Èyí ni òfin àkọ́kọ́ àti èyí ó tóbi jùlọ. 39 Èkejì ó tún dàbí rẹ̀ , Fẹ́ràn ọmọnìkejì rẹ gẹ́gẹ́ ara rẹ. 40 Lórí àwọn òfin méjèèjì yìí ni gbogbo òfin àti àwọn wòlíì rọ̀ mọ́."

Ọmọ ta ni Kristi?

41 àwọn Farisi ti ara wọn jọ, Jesu béèrè lọ́wọ́ wọn , 42 "ni nípa Kristi? Ọmọ ta ni òun ń ṣe?"

Wọ́n dáhùn , "Ọmọ Dafidi."

43 Ó fún wọn , "lo Dafidi, ̀ń darí, é Olúwa? Nítorí ó ,

44 " Olúwa sọ fún Olúwa mi ,

"Jókòó ọwọ́ ̀tún mi

títí èmi yóò fi fi àwọn ̀rẹ

abẹ́ ẹsẹ̀ rẹ." 

45 Ǹjẹ́ Dafidi é ni Olúwa,báwo ni òun ṣe jẹ́ ọmọ rẹ̀?" 46 ẹnìkan ó sọ ̀rọ̀ kan ni ìdáhùn, tún ẹni ó tún i léèrè ohun kan mọ́ láti ọjọ́ náà mọ́.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-