Publicidade

Romanos 2

Ìdájọ́ òdodo Ọlọ́run

1 Nítorí náà, aláìríwí ni ẹnikẹ́ni ó ó jẹ́ ń ni lẹ́jọ́, nítorí nínú ohun ìwọ ń ṣe ìdájọ́ ẹlòmíràn, ìwọ ń ara rẹ lẹ́bi; nítorí ìwọ ń dájọ́ ń ṣe ohun kan náà nínú èyí ìwọ ń ni lẹ́jọ́. 2 Ṣùgbọ́n àwa mọ̀ ìdájọ́ Ọlọ́run jẹ́ òtítọ́ si gbogbo àwọn ó ń ṣe irú ohun báwọ̀nyí. 3 Nítorí ìwọ ń ṣe ènìyàn lásán ń ṣe ìdájọ́ àwọn ń ṣe irú ohun báwọ̀nyí, ìwọ tìkára rẹ ń ṣe bẹ́̀, ìwọ ro èyí ìwọ o yọ nínú ìdájọ́ Ọlọ́run ? 4 Tàbí ìwọ ń gàn ọrọ̀ oore àti ìpamọ́ra àti sùúrù rẹ̀? Ìwọ ha mọ̀ oore Ọlọ́run ni ó ń ́ lọ ìrònúpìwàdà?

5 Ṣùgbọ́n gẹ́gẹ́ líle àti àìronúpìwàdà ọkàn rẹ̀, ìwọ ń to ìbínú jọ fún ara rẹ de ọjọ́ ìbínú àti ìfihàn ìdájọ́ òdodo Ọlọ́run. 6 Ọlọ́run yóò san án fún olúkúlùkù gẹ́gẹ́ iṣẹ́ rẹ̀. 7 Àwọn ẹni ń fi sùúrù nínú rere ṣíṣe, ògo àti ọlá àti àìdíbàjẹ́ ni yóò fi ìyè àìnípẹ̀kun fún. 8 Ṣùgbọ́n fún àwọn onímọ̀-tara-ẹni-nìkan, wọn gba òtítọ́ gbọ́, ṣùgbọ́n wọn ń tẹ̀̀búburú, wọn yóò ìrírí ìrunú àti ìbínú rẹ̀. 9 Ìpọ́njú àti ìrora, yóò lórí olúkúlùkù ọkàn ènìyàn ń hùwà ibi: ti Júù ṣáájú, àti àwọn Helleni pẹ̀; 10 ṣùgbọ́n ògo, àti ọlá, àti àlàáfíà, fún olúkúlùkù ẹni ń hùwà rere, fún Júù, ṣáájú àti fún àwọn Helleni pẹ̀. 11 Nítorí Ọlọ́run í ṣe ojúsàájú ènìyàn.

12 Gbogbo àwọn ó ṣẹ̀ àìlófin wọn ó ṣègbé láìlófin, àti iye àwọn ó ṣẹ̀ lábẹ́ òfin, àwọn ni a ó fi òfin lẹ́jọ́. 13 Nítorí í ṣe àwọn olùgbọ́ òfin ni ẹni ìdáláre lọ́dọ̀ Ọlọ́run, ṣùgbọ́n àwọn olùṣe òfin ni a ó láre. 14 Nítorí nígbà àwọn aláìkọlà, òfin, ṣe ohun ó nínú òfin nípa ìwà ̀, àwọn wọ̀nyí, jẹ́ òfin fún ara wọn wọn tilẹ̀ òfin. 15 Àwọn ẹni ó fihàn , a kọ̀iṣẹ́ òfin wọn lọ́kàn, ̀ọkàn wọn pẹ̀tún ń jẹ́ wọn lẹ́rìí, àti , èrò ọkàn wọn ó jẹ́ ̀ìfinisùn, ń gbè wọ́n lẹ́yìn ìsinsin yìí. 16 Èyí yóò farahàn ọjọ́ náà nígbà Ọlọ́run yóò tipasẹ̀ Jesu Kristi ṣe ìdájọ́ àwọn àṣírí ènìyàn gẹ́gẹ́ ìyìnrere mi.

Àwọn Júù àti òfin

17 Ṣùgbọ́n a ń pe ìwọ Júù, o sinmi òfin, o ń ṣògo nínú ìbálòpọ̀ rẹ̀ Ọlọ́run, 18 o mọ ìfẹ́ rẹ̀, o fọwọ́ohun ó dára jùlọ, nítorí a ti kọ́ òfin; 19 o ara rẹ lójú ìwọ ni amọ̀àwọn afọ́, ìmọ́lẹ̀ fún àwọn ó ni òkùnkùn, 20 Olùkọ́ àwọn aláìmòye, olùkọ́ àwọn ọmọdé, ẹni ó ètò ìmọ̀ àti òtítọ́ òfin lọ́wọ́. 21 Ǹjẹ́ ìwọ o ń kọ́ ẹlòmíràn, ìwọ kọ́ ara rẹ? Ìwọ ó ń wàásù ènìyàn jalè, ìwọ ha ń jalè ? 22 Ìwọ o , ènìyàn ṣe panṣágà, ìwọ ń ṣe panṣágà ? Ìwọ o kórìíra òrìṣà, ìwọ ń ja tẹmpili olè ? 23 Ìwọ ti ń ṣògo nínú òfin, ìwọ ha ń bu Ọlọ́run ni ọlá nípa rírú òfin? 24 Nítorí gẹ́gẹ́ a ti kọ ́, "Orúkọ Ọlọ́run à di ìsọ̀rọ̀-òdì láàrín àwọn aláìkọlà nítorí yín."

25 Nítorí ìkọlà èrè nítòótọ́, ìwọ pa òfin mọ́; ṣùgbọ́n ìwọ jẹ́ arúfin, ìkọlà rẹ di àìkọlà. 26 Nítorí náà àwọn aláìkọlà pa ìlànà òfin mọ́, a yóò ha wọ́n àwọn a kọ nílà ? 27 Aláìkọlà nípa àdánidá, ó pa òfin mọ́, yóò ̀bi fún ìwọ ó jẹ́ arúfin nípa ti àkọsílẹ̀ òfin àti ìkọlà.

28 í ṣe èyí ó farahàn òde ni Júù, bẹ́̀ ni í ṣe èyí ó farahàn ara ni ìkọlà. 29 Ṣùgbọ́n Júù ti inú ni Júù, àti ìkọlà ni ti ọkàn nínú ̀í ṣe ti àkọsílẹ̀, ìyìn ẹni lọ́dọ̀ ènìyàn, ṣe lọ́dọ̀ Ọlọ́run.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-