Publicidade

Romanos 6

12 Nítorí náà ṣe jẹ́ ̀ṣẹ̀ jẹ ọba lórí ara kíkú yín ó ba à máa ṣe ìfẹ́kúfẹ̀́ rẹ̀. 13 ṣe jẹ́ ̀ara yín kan di ohun èlò ohun búburú, nípa ̀ṣẹ̀ dídá. Ṣùgbọ́n fi wọn fún Ọlọ́run pátápátá. Wọ́n ti di ààyè, jẹ́ wọn di ohun èlò ọwọ́ Ọlọ́run, ó wọ́n fún àwọn ìlànà rẹ̀ ó dára. 14 Nítorí ̀ṣẹ̀ yóò tún ipá lórí yín mọ́, nítorí ̀yin lábẹ́ ìdè òfin, ṣe lábẹ́ oore-ọ̀fẹ́.

Ẹrú ìṣòdodo

15 Ǹjẹ́ èyí túmọ̀ , nísinsin yìí, a tẹ̀síwájú láti máa dẹ́ṣẹ̀ láìbìkítà, nítorí ìgbàlà wa dúró nípa òfin mọ́, ṣe nípa gbígba oore-ọ̀fẹ́ Ọlọ́run! 16 Àbí ̀yin mọ̀ , ẹnikẹ́ni yan ̀ó fẹ́? yan ̀ṣẹ̀ ti o yọrí si ikú tàbí ìgbọ́ràn ti o yọrí ìdáláre. Ẹnikẹ́ni fi ara yín fún, òun náà ni yóò jẹ́ ̀yín, ̀yin yóò jẹ́ ẹrú rẹ̀. 17 Ṣùgbọ́n ọpẹ́ ni fún Ọlọ́run , ̀yin ti jẹ́ ẹrú ̀ṣẹ̀ , ̀yin jẹ́ olùgbọ́ran láti ọkàn àpẹẹrẹ ̀kọ́ èyí Ọlọ́run fi yín lọ́wọ́. 18 Nísinsin yìí, ti dòmìnira kúrò lọ́wọ́ ̀yín àtijọ́, èyí í ṣe ̀ṣẹ̀, ti di ẹrú ̀tuntun èyí ni òdodo.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-