Pular para o conteúdo
Publicidade

Romu 6

12 Nítorí náà ṣe jẹ́ ̀ṣẹ̀ jẹ ọba lórí ara kíkú yín ó ba à máa ṣe ìfẹ́kúfẹ̀́ rẹ̀. 13 6.13: Ro 6.19; 7.5; 12.1.ṣe jẹ́ ̀ara yín kan di ohun èlò ohun búburú, nípa ̀ṣẹ̀ dídá. Ṣùgbọ́n fi wọn fún Ọlọ́run pátápátá. Wọ́n ti di ààyè, jẹ́ wọn di ohun èlò ọwọ́ Ọlọ́run, ó wọ́n fún àwọn ìlànà rẹ̀ ó dára. 14 6.14: Ro 8.2.Nítorí ̀ṣẹ̀ yóò tún ipá lórí yín mọ́, nítorí ̀yin lábẹ́ ìdè òfin, ṣe lábẹ́ oore-ọ̀fẹ́.

Ẹrú ìṣòdodo

15 6.15: Ro 3.8; 6.1. Ǹjẹ́ èyí túmọ̀ , nísinsin yìí, a tẹ̀síwájú láti máa dẹ́ṣẹ̀ láìbìkítà, nítorí ìgbàlà wa dúró nípa òfin mọ́, ṣe nípa gbígba oore-ọ̀fẹ́ Ọlọ́run! 16 6.16: Mt 6.24; Jh 8.34; Ro 12.1.Àbí ̀yin mọ̀ , ẹnikẹ́ni yan ̀ó fẹ́? yan ̀ṣẹ̀ ti o yọrí si ikú tàbí ìgbọ́ràn ti o yọrí ìdáláre. Ẹnikẹ́ni fi ara yín fún, òun náà ni yóò jẹ́ ̀yín, ̀yin yóò jẹ́ ẹrú rẹ̀. 17 Ṣùgbọ́n ọpẹ́ ni fún Ọlọ́run , ̀yin ti jẹ́ ẹrú ̀ṣẹ̀ , ̀yin jẹ́ olùgbọ́ran láti ọkàn àpẹẹrẹ ̀kọ́ èyí Ọlọ́run fi yín lọ́wọ́. 18 6.18: Ro 8.2.Nísinsin yìí, ti dòmìnira kúrò lọ́wọ́ ̀yín àtijọ́, èyí í ṣe ̀ṣẹ̀, ti di ẹrú ̀tuntun èyí ni òdodo.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também