Publicidade

Tiago 1

1 Jakọbu, ìránṣẹ́ Ọlọ́run àti ti Jesu Kristi Olúwa,

àwọn ̀méjìlá ó fọ́n káàkiri, orílẹ̀-èdè:

Àlàáfíà.

Àwọn ìṣòro àti àwọn ìdánwò

2 ̀yin ará mi, nígbà ̀yin bọ́ sínú onírúurú ìdánwò, ka gbogbo rẹ̀ ayọ̀; 3 nítorí ̀yin mọ̀ , ìdánwò ìgbàgbọ́ yín ń ṣiṣẹ́ sùúrù. 4 Ṣùgbọ́n jẹ́ sùúrù ó ṣiṣẹ́ àṣepé, ̀yin ó jẹ́ pípé àti aláìlábùkù ṣe aláìní ohunkóhun. 5 ó ku ọgbọ́n fún ẹnikẹ́ni, ó béèrè lọ́wọ́ Ọlọ́run ẹni fi fún gbogbo ènìyàn ̀pọ̀lọpọ̀, í ka àlébù ; a ó fi fún un. 6 Ṣùgbọ́n nígbà òun béèrè ìgbàgbọ́, àìṣiyèméjì rárá. Nítorí ẹni ó ń iyèméjì dàbí ìgbì omi Òkun, à ń ti ọwọ́ afẹ́fẹ́ síwá sẹ́yìn, a ń u sókè. 7 irú ènìyàn bẹ́̀ ṣe , òun yóò ohunkóhun gbà lọ́wọ́ Olúwa; 8 Ó jẹ ènìyàn oníyèméjì aláìlèdúró ̀rẹ̀ gbogbo.

9 Ṣùgbọ́n jẹ́ arákùnrin ó ń ṣe onírẹ̀lẹ̀ máa ṣògo ipò gíga. 10 Àti ọlọ́rọ̀, ìrẹ̀sílẹ̀, nítorí ìtànná koríko ni yóò kọjá lọ. 11 Nítorí oòrùn ti òun ti ooru gbígbóná yóò gbẹ́ koríko, ìtànná rẹ̀ rẹ̀ dànù, ẹwà ojú rẹ̀ parun: bẹ́̀ pẹ̀ni ọlọ́rọ̀ yóò ṣègbé ̀rẹ̀.

12 Ìbùkún ni fún ọkùnrin ó fi ọkàn rán ìdánwò; nítorí nígbà ó yege, yóò gba adé ìyè, Olúwa ti ṣèlérí fún àwọn ó fẹ́ .

13 ẹnikẹ́ni a dánwò ó ṣe , "Láti ọwọ́ Ọlọ́run ni a ti dán mi ." Nítorí a fi búburú dán Ọlọ́run , òun náà í í dán ẹnikẹ́ni ; 14 ṣùgbọ́n olúkúlùkù ni a ń dánwò nígbà a fi ọwọ́ ìfẹ́kúfẹ̀́ ara rẹ̀ á lọ a tàn án jẹ. 15 Ǹjẹ́, ìfẹ́kúfẹ̀́ nígbà ó lóyún a ̀ṣẹ̀, àti ̀ṣẹ̀ náà nígbà ó dàgbà tán, a ikú.

16 a ṣe tàn yín jẹ, ̀yin ará mi olùfẹ́. 17 Gbogbo ̀bùn rere àti gbogbo ̀bùn pípé láti òkè ni ó ti , ó sọ̀kalẹ̀ láti ̀dọ̀ baba ìmọ́lẹ̀ , lọ́dọ̀ ẹni yípadà gẹ́gẹ́ òjìji àyídà. 18 Ó pinnu láti fi ̀rọ̀ òtítọ́ wa àwa ó le jẹ́ àkọ́so nínú ohun gbogbo ó .

Gbígbọ́ àti ṣíṣe ọrọ̀ náà

19 mọ èyí, ̀yin ará mi olùfẹ́; jẹ́ olúkúlùkù ènìyàn ó máa yára láti gbọ́, ó lọ́ra láti fọhùn, ó si lọ́ra láti bínú; 20 nítorí ìbínú ènìyàn í ṣiṣẹ́ òdodo irú èyí Ọlọ́run ń fẹ́. 21 Nítorí náà, lépa láti borí gbogbo èérí àti ìwà búburú ó gbilẹ̀ yíká, fi ọkàn tútù gba ̀rọ̀ náà a gbìn, ó gba ọkàn yín .

22 kan jẹ́ olùgbọ́ ̀rọ̀ náà lásán, ba à ti ipa èyí tan ara yín jẹ́. ṣe ohun ó sọ. 23 Nítorí ẹnikẹ́ni jẹ́ olùgbọ́ ̀rọ̀ náà jẹ́ olùṣe, òun dàbí ọkùnrin ó ń ṣàkíyèsí ojú ara rẹ̀ nínú dígí 24 nítorí, lẹ́yìn ó ti ṣàkíyèsí ara rẹ̀, ó tirẹ̀ lọ, lójúkan náà òun gbàgbé òun ti . 25 Ṣùgbọ́n ẹni ó ń wo inú òfin pípé, òfin òmìnira ni, ó dúró nínú rẹ̀, òun jẹ́ olùgbọ́ ń gbàgbé ṣe olùṣe rẹ̀, òun yóò jẹ́ alábùkún nínú iṣẹ́ rẹ̀.

26 ẹnikẹ́ni òun ń sin Ọlọ́run nígbà ahọ́n rẹ̀ ìjánu, ó ń tan ọkàn ara rẹ̀ jẹ, ìsìn rẹ̀ jẹ́ asán. 27 Ìsìn mímọ́ àti aláìléèérí níwájú Ọlọ́run àti Baba ni èyí, láti máa bojútó àwọn aláìní baba àti àwọn opó nínú ìpọ́njú wọn, àti láti pa ara rẹ̀ mọ́ láìlábàwọ́n kúrò nínú ayé.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-