Publicidade

Tiago 4

Ìyọ̀ǹda ara ẹni fún Ọlọ́run

1 Níbo ni ogun ti , níbo ni ìjà ti láàrín yín? Ìfẹ́kúfẹ̀́ ara yín ha kọ́ ni ó ń jagun nínú àwọn ̀ara yín ? 2 ̀yin ń fẹ́ ìfẹ́kúfẹ̀́, , ̀yin ń pànìyàn, ń ṣe ìlara, le : ̀yin ń , ̀yin ń jagun; , nítorí ̀yin béèrè. 3 ̀yin béèrè, gbà, nítorí ̀yin ṣì béèrè, ̀yin ó ó fún ìfẹ́kúfẹ̀́ ara yín.

4 ̀yin panṣágà ọkùnrin, àti panṣágà obìnrin, mọ̀ ìbárẹ́ ayé ìṣọ̀Ọlọ́run ni? Nítorí náà ẹni ó fẹ́ láti jẹ́ ̀rẹ́ ayé di ̀Ọlọ́run. 5 ̀yin ṣe Ìwé Mímọ́ sọ lásán , ̀ó fi sínú wa ń jowú gidigidi lórí wa? 6 Ṣùgbọ́n ó fún ni oore-ọ̀fẹ́ i. Nítorí náà ni ìwé mímọ́ ṣe ,

"Ọlọ́run kọ ojú ìjà àwọn agbéraga,

ṣùgbọ́n ó fi oore-ọ̀fẹ́ fún àwọn onírẹ̀lẹ̀ ọkàn."

7 Nítorí náà, tẹríba fún Ọlọ́run. kọ ojú ìjà èṣù, òun ó kúrò lọ́dọ̀ yín. 8 súnmọ́ Ọlọ́run, òun ó súnmọ́ yín. wẹ ọwọ́ yín mọ́, ̀yin ẹlẹ́ṣẹ̀; ṣe ọkàn yín mímọ́, ̀yin oníyèméjì. 9 banújẹ́, ṣọ̀fọ̀, hu fún ẹkún. jẹ́ ̀rín yín ó di ̀fọ̀, àti ayọ̀ yín ó di ìbànújẹ́. 10 rẹ ara yín sílẹ̀ níwájú Olúwa, òun ó gbé yín ga.

11 Ará, ṣe sọ̀rọ̀ ibi ara yín. Ẹni ó ń sọ̀rọ̀ ibi arákùnrin rẹ̀, ó ń arákùnrin rẹ̀ lẹ́jọ́, ó ń sọ̀rọ̀ ibi òfin, ó ń òfin lẹ́jọ́; ṣùgbọ́n ìwọ ń òfin lẹ́jọ́, ìwọ í ṣe olùfẹ́ òfin, ṣe onídàájọ́. 12 Aṣòfin àti onídàájọ́ kan ṣoṣo ó ń bẹ, àní ẹni ó gbàlà ó le parun, ṣùgbọ́n ta ni ìwọ ó ń ẹnìkejì rẹ lẹ́jọ́?

ṣe ìlérí nípa ọjọ́ ̀la

13 nísinsin yìí, ̀yin ó ń , "Lónìí tàbí lọ́la àwa ó lọ ìlú báyìí, a ó ṣe ọdún kan níbẹ̀, a ó ṣòwò, a ó jèrè." 14 Nígbà ̀yin mọ ohun yóò lọ́la. ni ̀yín? Ìkùùkuu à ni yín, ó hàn nígbà díẹ̀, lẹ́yìn náà a túká lọ. 15 Èyí ̀ fi , "Olúwa fẹ́, àwa yóò láààyè, àwa ó ṣe èyí tàbí èyí i ." 16 Ṣùgbọ́n nísinsin yìí, ̀yin ń gbéraga nínú ìfọ́nnu yín, gbogbo irú ìfọ́nnu bẹ́̀, ibi ni. 17 Nítorí náà ẹni ó mọ rere í ṣe ṣe é, ̀ṣẹ̀ ni fún un.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-