Pular para o conteúdo
Publicidade

Agradecimento pela vida

Por Bíblia Online

Agradecer pela vida é reconhecer que cada respiração é dom de Deus. Toda criatura que tem fôlego louve ao Senhor — porque Ele nos formou e nos sustenta com amor.

Jẹ́ gbogbo ohun ó ̀yin Olúwa.

fi ìyìn fún Olúwa.

fi ìyìn fún Olúwa.

Fi ìyìn fún Olúwa, ìwọ ọkàn mi.

Èmi yóò yin Olúwa gbogbo ayé mi,

èmi yóò kọrin ìyìn Ọlọ́run, níwọ̀n ìgbà mo láààyè.

Nítorí ìwọ ni ó ọkàn mi;

ìwọ ni ó mọ́lẹ̀ nínú ìyá mi.

Èmi yóò yìn , nítorí tẹ̀tẹ̀àti tìyanu tìyanu a mi;

ìyanu iṣẹ́ rẹ;

èyí ni ọkàn mi mọ̀ dájúdájú.

̀ara mi pamọ́ kúrò lọ́dọ̀ rẹ,

nígbà a mi ìkọ̀kọ̀.

a ń ṣiṣẹ́ àràbarà ìhà ìsàlẹ̀ ilẹ̀ ayé,

ojú rẹ ti ohun ara mi

nígbà a ì ṣe ,

àti nínú ìwé rẹ ni a ti kọ ̀kọ̀̀kan wọn ,

ọjọ́ a wọn,

nígbà wọn tilẹ̀ ì .

gbogbo ayé mi n ó kọrin Olúwa:

èmi ó kọrin ìyìn Olúwa

níwọ̀n ìgbà mo láààyè.

Jẹ́ ̀kọ́ mi ó tẹ́ lọ́rùn

mo ti ń yọ̀ nínú Olúwa.

Olúwa Ọlọ́run ni ó wa,

̀yin ó mọ̀

tirẹ̀ ni àwa, àwa ènìyàn rẹ̀

àti àgùntàn pápá rẹ̀.

lọ ẹnu-ọ̀rẹ̀ pẹ̀ọpẹ́

àti àgbàlá rẹ̀ pẹ̀ìyìn;

fi ọpẹ́ àti ìyìn fún orúkọ rẹ̀.

Báwo ni ìṣeun ìdúró ṣinṣin ìfẹ́ rẹ ti ! Ọlọ́run!

gbogbo ọmọ ènìyàn le abẹ́ òjìji ìyẹ́ rẹ.

Àsè ilé rẹ yóò tẹ́ wọn lọ́rùn gidigidi;

ìwọ yóò wọn mu nínú odò inú dídùn rẹ.

Nítorí pẹ̀rẹ ni orísun ìyè :

nínú ìmọ́lẹ̀ rẹ ni àwa yóò ìmọ́lẹ̀.

Èmi yóò kókìkí i rẹ, Olúwa,

nítorí ìwọ ni ó gbé mi lékè

ìwọ jẹ́ àwọn ̀mi ó yọ̀ .

Olúwa Ọlọ́run mi, èmi ́ fún ìrànlọ́wọ́,

ìwọ ti sàn.

Olúwa, ìwọ ti yọ ọkàn mi jáde kúrò nínú isà òkú,

mi padà bọ̀ sípò alààyè èmi ba à lọ sínú ihò.

Èmi ó yìn ́, Olúwa, pẹ̀gbogbo ọkàn mi;

èmi ó sọ ti ìyanu rẹ gbogbo.

Inú mi yóò dùn, èmi yóò yọ̀ nínú rẹ;

èmi ó kọrin ìyìn orúkọ rẹ, Ìwọ ̀gá-Ògo jùlọ.

máa dúpẹ́ nígbà gbogbo fún ohun gbogbo lọ́wọ́ Ọlọ́run, àní Baba, orúkọ Jesu Kristi Olúwa .

Ìbùkún ti ̀Mímọ́ nínú Kristi

Ògo ni fún Ọlọ́run àti Baba Jesu Kristi Olúwa wa, ẹni ó ti bùkún wa láti inú ̀run pẹ̀àwọn ìbùkún ̀gbogbo nínú Kristi.

Ọpẹ́ ni fún Ọlọ́run nítorí aláìlèfẹnusọ ̀bùn rẹ̀!

a máa dúpẹ́ nígbà gbogbo lọ́wọ́ Baba, ẹni ó yín láti jẹ́ alábápín nínú ogún àwọn ẹni mímọ́ nínú ìjọba ìmọ́lẹ̀. Nítorí ó ti wa gbà kúrò nínú agbára òkùnkùn ó wa ìjọba Ọmọ ó fẹ́ràn. Nínú ẹni a ìràpadà, àti ìdáríjì ̀ṣẹ̀.

Títóbi Kristi

Kristi ni àwòrán Ọlọ́run a le , àkọ́gbogbo ̀. Nítorí nípa rẹ̀ a ohun gbogbo: àwọn ohun ń bẹ ̀run àti ayé, ohun a àti èyí a , wọn ìbá ṣe ìtẹ́, tàbí agbára, tàbí àṣẹ, nípasẹ̀ rẹ̀ ni a ohun gbogbo àti fún un. Ó ti ṣáájú ohunkóhun , nínú rẹ̀ ni a so ohun gbogbo papọ̀ ṣọ̀kan.

Nígbà ti jẹ tán yin Olúwa Ọlọ́run yín fún pípèsè ilẹ̀ rere fún un yín.

Olúwa, ìwọ gba ẹjọ́ mi ,

o ra ̀mi padà.

Èmi sọ̀kalẹ̀ lọ ìsàlẹ̀ àwọn òkè ńlá;

ilẹ̀ ayé pẹ̀ìdènà rẹ̀ mi títí:

ṣùgbọ́n ìwọ ti ̀mi sókè láti inú ibú ,

Olúwa Ọlọ́run mi.

"Nígbà ó rẹ ọkàn mi nínú mi,

èmi rántí rẹ, Olúwa,

àdúrà mi ̀dọ̀ rẹ,

nínú tẹmpili mímọ́ rẹ.

Seja o primeiro