Publicidade

Efésios 5

1 Nítorí náà, máa ṣe àfarawé Ọlọ́run àwọn olùfẹ́ ọmọ, 2 máa rìn ìfẹ́, gẹ́gẹ́ Kristi pẹ̀ti fẹ́ wa, ó fi ara rẹ̀ fún wa ọrẹ àti ẹbọ fún Ọlọ́run fún òórùn dídùn.

3 Ṣùgbọ́n àgbèrè àti gbogbo ìwà èérí, tàbí ojúkòkòrò, a tilẹ̀ dárúkọ rẹ̀ láàrín yín mọ́, ó ti yẹ àwọn ènìyàn mímọ́. 4 Ìbá à ṣe ìwà ̀bùn, àti ìṣọ̀rọ̀ òmùgọ̀, tàbí ìṣẹ̀fẹ̀ àwọn ohun tọ́; ṣùgbọ́n kúkú máa dúpẹ́. 5 Nítorí ̀yin mọ èyí dájú , panṣágà, tàbí aláìmọ́ ènìyàn, tàbí wọ̀bìà (í ṣé abọ̀rìṣà), yóò ni ìpín kan ni ìjọba Kristi àti Ọlọ́run. 6 ṣe jẹ́ ẹnikẹ́ni fi ̀rọ̀ asán tàn yín jẹ: nítorí nípasẹ̀ nǹkan wọ̀nyí ìbínú Ọlọ́run fi ń bọ̀ sórí àwọn ọmọ aláìgbọ́ràn. 7 Nítorí náà ṣe jẹ́ alájọpín pẹ̀wọn.

8 Nítorí ̀yin jẹ́ òkùnkùn lẹ́̀kan ṣùgbọ́n nísinsin yìí, ̀yin ìmọ́lẹ̀, nípa Olúwa: máa rín gẹ́gẹ́ àwọn ọmọ ìmọ́lẹ̀ 9 (nítorí èso ̀ni ìṣoore, àti òdodo àti òtítọ́). 10 máa wádìí ohun í ṣe ìtẹ́wọ́gbà fún Olúwa. 11 ṣe àwọn oníṣẹ́ òkùnkùn kẹ́gbẹ́ pọ̀, ṣùgbọ́n kúkú máa wọn . 12 Nítorí ìtìjú tilẹ̀ ni láti máa sọ̀rọ̀ nǹkan wọ̀n-ọn-nì àwọn aláìgbọ́ràn ń ṣe ìkọ̀kọ̀. 13 Ṣùgbọ́n ohun gbogbo a síta ni ìmọ́lẹ̀ ń hàn: nítorí ohunkóhun ó fi nǹkan hàn, ìmọ́lẹ̀ ni. 14 Nítorí náà ni ó ṣe ,

", ìwọ̀ ẹni ó sun,

jíǹde kúrò nínú òkú

Kristi yóò fún ìmọ́lẹ̀."

15 Nítorí náà kíyèsi láti máa rìn ìwà pípé, í ṣé àwọn òmùgọ̀, ṣùgbọ́n àwọn ọlọ́gbọ́n; 16 máa ra ìgbà padà, nítorí búburú àwọn ọjọ́. 17 Nítorí náà, ṣé jẹ aláìlóye, ṣùgbọ́n máa mòye ohun ìfẹ́ Olúwa jásí. 18 ṣe wáìnì àmupara, nínú èyí rúdurùdu ; ṣùgbọ́n kún fún ̀Mímọ́. 19 máa ara yín sọ̀rọ̀ nínú Saamu, àti orin ìyìn, àti orin ̀, máa kọrin, máa kọrin dídùn ọkàn yín Olúwa. 20 máa dúpẹ́ nígbà gbogbo fún ohun gbogbo lọ́wọ́ Ọlọ́run, àní Baba, orúkọ Jesu Kristi Olúwa .

Àwọn aya àti ọkọ

21 máa tẹríba fún ara yín ìbẹ̀Ọlọ́run.

22 ̀yin aya, máa tẹríba fún àwọn ọkọ yín, gẹ́gẹ́ fún Olúwa. 23 Nítorí ọkọ ni ó ń ṣe orí aya, gẹ́gẹ́ Kristi i ṣe orí ìjọ, òun si ń ṣe ara rẹ̀, Òun ni Olùgbàlà rẹ̀. 24 Nítorí náà gẹ́gẹ́ ìjọ i tẹríba fún Kristi, bẹ́̀ àwọn aya máa ṣe ọkọ wọn ohun gbogbo.

25 ̀yin ọkọ, fẹ́ràn àwọn aya yín, gẹ́gẹ́ Kristi fẹ́ràn ìjọ, ó fi ara rẹ̀ fún un. 26 òun sọ ́ di mímọ́ lẹ́yìn ó fi ̀rọ̀ wẹ̀ ́ nínú agbada omí. 27 òun un sọ́dọ̀ ara rẹ̀ ìjọ ó ògo àìlábàwọ́n, tàbí àlébù kan, tàbí irú nǹkan bá-wọ̀n-ọn-nì: ṣùgbọ́n ó jẹ́ mímọ́ àti aláìlábùkù. 28 Bẹ́̀ ó tọ́ àwọn ọkùnrin máa fẹ́ràn aya wọn gẹ́gẹ́ ara àwọn fúnra wọn. 29 Nítorí ẹnìkan ó ti kórìíra ara rẹ̀; ṣe ó máa bọ́ ó máa ṣìkẹ́ rẹ̀ gẹ́gẹ́ Kristi ti ń ṣe ìjọ. 30 Nítorí àwa ni ̀ara rẹ̀, àti ẹran-ara rẹ̀, àti egungun ara rẹ̀. 31 Nítorí èyí ọkùnrin yóò fi baba àti ìyá rẹ̀ sílẹ̀, òun yóò dàpọ̀ mọ́ aya rẹ̀, àwọn méjèèjì yóò di ara kan. 32 Àṣírí ńlá èyí: ṣùgbọ́n èmí ń sọ nípá ti Kristi àti ìjọ. 33 Ṣùgbọ́n olúkúlùkù yín fẹ́ràn aya rẹ̀, bẹ́̀ gẹ́gẹ́ òun fúnra rẹ̀; aya ó bọ̀wọ̀ fún ọkọ rẹ̀.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-