Pular para o conteúdo
Publicidade

Joṣua 18

Pínpín ilẹ̀ ó

1 Gbogbo ìjọ àwọn ọmọ Israẹli péjọ Ṣilo, wọ́n si kọ́ àgọ́ ìpàdé ibẹ̀. Gbogbo ilẹ̀ náà abẹ́ àkóso wọn, 2 ṣùgbọ́n ó ku ̀méje nínú àwọn ọmọ Israẹli ì gba ogún ìní wọn.

3 Báyìí ni Joṣua sọ fún àwọn ọmọ Israẹli, "Báwo ni ̀yin yóò ṣe dúró pẹ́ , gba ilẹ̀ ìní Olúwa Ọlọ́run àwọn baba yín ti fi fún yín? 4 yan àwọn ọkùnrin mẹ́ta nínú ̀kọ̀̀kan. Èmi yóò rán wọn jáde láti lọ bojú wo ilẹ̀ náà káàkiri, wọn yóò ṣe àpèjúwe rẹ̀, gẹ́gẹ́ ìní ẹni kọ̀̀kan. Nígbà náà ni wọn yóò padà tọ̀ . 5 ̀yin yóò pín ilẹ̀ náà ̀méje Juda dúró ilẹ̀ rẹ̀ ni ìhà gúúsù àti ilé Josẹfu ilẹ̀ rẹ̀ ìhà àríwá. 6 Lẹ́yìn ìgbà kọ àpèjúwe ̀méjèèje ilẹ̀ náà, wọn ̀dọ̀ mi ibí, èmi ó ṣẹ́ kèké fún yín iwájú Olúwa Ọlọ́run wa. 7 Ṣùgbọ́n àwọn ọmọ Lefi ìpín àárín yín, nítorí iṣẹ́ àlùfáà. Olúwa ni ìní wọ́n. Gadi, Reubeni àti ìdajì ̀Manase, ti gba ìní wọn ìhà ìlà-oòrùn Jordani. Mose ìránṣẹ́ Olúwa ti fi fún wọn."

8 àwọn ọkùnrin náà ti bẹ̀rẹ̀ ìrìnàjò wọn láti fojú díwọ̀n ilẹ̀ náà, Joṣua pàṣẹ fún wọn , "lọ fojú díwọ̀n ilẹ̀ náà káàkiri, kọ àpèjúwe rẹ̀. Lẹ́yìn náà padà tọ̀ , èmi ò ṣẹ́ kèké fún yin ibí Ṣilo iwájú Olúwa." 9 Báyìí ni àwọn ọkùnrin náà lọ, wọ́n la ilẹ̀ náà . Wọ́n kọ àpèjúwe rẹ̀ orí ìwé kíká ìlú, ̀méje, wọ́n padà tọ Joṣua lọ ibùdó Ṣilo.

10 Joṣua ṣẹ́ gègé fún wọn Ṣilo iwájú Olúwa, Joṣua pín ilẹ̀ náà fún àwọn Israẹli gẹ́gẹ́ ìpín ̀wọn ibẹ̀.

Ìpín ti ̀Benjamini

11 Ìbò náà sórí ̀Benjamini, agbo ilé, agbo ilé. Ilẹ̀ ìpín wọn láàrín ti ̀Juda àti Josẹfu.

12 ìhà àríwá ààlà wọn bẹ̀rẹ̀ Jordani, ó kọjá lọ gẹ̀rẹ́gẹ̀rẹ́ Jeriko ìhà àríwá, ó forí ìwọ̀-oòrùn ìlú òkè, jáde aginjù Beti-Afeni. 13 Láti ibẹ̀ ààlà náà tún kọjá lọ ìhà gúúsù ̀Lusi (í ṣe Beteli) ó Atarotu-Addari, orí òkè ó gúúsù Beti-Horoni.

14 Láti òkè ó kọjú Beti-Horoni gúúsù ààlà náà gúúsù ìhà ìwọ̀-oòrùn, ó jáde Kiriati-Baali (í ṣe Kiriati-Jearimu), ìlú àwọn ènìyàn Juda. Èyí ni ìhà ìwọ̀-oòrùn.

15 Ìhà gúúsù bẹ̀rẹ̀ ìpẹ̀kun Kiriati-Jearimu ìwọ̀-oòrùn, ààlà náà ibi ìsun omi Nefitoa. 16 Ààlà náà lọ ìsàlẹ̀ ẹsẹ̀ òkè ó kọjú àfonífojì Beni-Hinnomu, àríwá àfonífojì Refaimu. O sọ̀kalẹ̀ lọ àfonífojì Hinnomu apá gúúsù gẹ̀rẹ́gẹ̀rẹ́ òkè ìlú Jebusi, ó lọ bẹ́̀ títí En-Rogeli. 17 Nígbà náà ni ó yípo ìhà àríwá, ó lọ Ẹni-Ṣemeṣi, ó tẹ̀síwájú Geliloti ó kọjú òkè Adummimu, ó sọ̀kalẹ̀ ibi Òkúta Bohani ọmọ Reubeni. 18 Ó tẹ̀síwájú títí gẹ̀rẹ́gẹ̀rẹ́ òkè Beti-Araba, ó sọ̀kalẹ̀ lọ aginjù. 19 Nígbà náà ni ó lọ gẹ̀rẹ́gẹ̀rẹ́ òkè Beti-Hogla, ó jáde àríwá etí bèbè Òkun Iyọ̀, ẹnu odò Jordani gúúsù. Èyí ni ààlà ti gúúsù.

20 Odò Jordani jẹ́ ààlà ìhà ìlà-oòrùn.

Ìwọ̀nyí àwọn ààlà ti ó sàmì ìní àwọn ìdílé Benjamini gbogbo àwọn àyíká wọn.

21 ̀Benjamini agbo ilé, agbo ilé ni àwọn ìlú wọ̀nyí:

Jeriko, Beti-Hogla, Emeki-Keṣiṣi, 22 Beti-Araba, Semaraimu, Beteli, 23 Affimu, Para, Ofira 24 Kefari, Ammoni, Ofini àti Geba; àwọn ìlú méjìlá àti ìletò wọn.

25 Gibeoni, Rama, Beeroti, 26 Mispa, Kefira, Mosa, 27 Rekemu, Irpeeli, Tarala, 28 Ṣela, Haelefi, ìlú Jebusi (í ṣe Jerusalẹmu), Gibeah àti Kiriati, àwọn ìlú mẹ́rìnlá àti ìletò wọn.

Èyí ni ìní Benjamini fún ìdílé rẹ̀.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também