Pular para o conteúdo
Publicidade

Nehemiah 12

Àwọn àlùfáà àti àwọn ọmọ Lefi

1 Àwọn wọ̀nyí ni àwọn àlùfáà àti àwọn ọmọ Lefi ó Serubbabeli ọmọ Ṣealitieli àti Jeṣua padà:

Seraiah, Jeremiah, Esra,

2 Amariah, Malluki, Hattusi,

3 Ṣekaniah, Rehumu, Meremoti,

4 Iddo, Ginetoni, Abijah,

5 Mijamini, Moadiah, Bilgah,

6 Ṣemaiah, Joiaribu, Jedaiah,

7 Sallu, Amoki, Hilkiah, àti Jedaiah.

Wọ̀nyí ni olórí àwọn àlùfáà àti àwọn ẹlẹgbẹ́ wọn ìgbà ayé e Jeṣua.

8 Àwọn ọmọ Lefi ni Jeṣua, Binnui, Kadmieli, Ṣerebiah, Juda àti Mattaniah ẹni òun pẹ̀àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀, ni wọn ṣe àkóso orin ìdúpẹ́. 9 Bakbukiah àti Unni, àwọn ẹlẹgbẹ́ wọn dúró òdìkejì wọn nínú ìsìn.

10 Jeṣua ni baba Joiakimu,

Joiakimu ni baba Eliaṣibu,

Eliaṣibu ni baba Joiada,

11 Joiada ni baba Jonatani,

Jonatani ni baba Jaddua.

12 ìgbé ayé Joiakimu, wọ̀nyí ni àwọn olórí àwọn ìdílé àwọn àlùfáà:

ti ìdílé Seraiah, Meraiah;

ti ìdílé Jeremiah, Hananiah;

13 ti ìdílé Esra, Meṣullamu;

ti ìdílé Amariah, Jehohanani;

14 ti ìdílé Malluki, Jonatani;

ti ìdílé Ṣekaniah, Josẹfu;

15 ti ìdílé Harimu, Adna;

ti ìdílé Meraioti Helikai;

16 ti ìdílé Iddo, Sekariah;

ti ìdílé Ginetoni, Meṣullamu;

17 ti ìdílé Abijah, Sikri;

ti ìdílé Miniamini àti ti ìdílé Moadiah, Piltai;

18 ti ìdílé Bilgah, Ṣammua;

ti ìdílé Ṣemaiah, Jehonatani;

19 ti ìdílé Joiaribu, Mattenai;

ti ìdílé Jedaiah, Ussi;

20 ti ìdílé Sallu, Kallai;

ti ìdílé Amoki, Eberi;

21 ti ìdílé Hilkiah, Haṣabiah;

ti ìdílé Jedaiah, Netaneli.

22 Àwọn olórí ìdílé àwọn ọmọ Lefi ìgbà ayé Eliaṣibu, Joiada, Johanani àti Jaddua, àti pẹ̀ti àwọn àlùfáà ni a kọ sílẹ̀ ìgbà ìjọba Dariusi ará Persia. 23 Àwọn olórí ìdílé láàrín àwọn ọmọ Lefi títí di àkókò Johanani ọmọ Eliaṣibu ni a kọ sílẹ̀ nínú ìwé ìtàn. 24 Àti àwọn olórí àwọn ọmọ Lefi ni Haṣabiah, Ṣerebiah, Jeṣua ọmọ Kadmieli, àti àwọn ẹlẹgbẹ́ wọn, wọ́n dúró ìdojúkojú wọn láti fi ìyìn àti láti dúpẹ́, apá kan ń èkejì lóhùn, gẹ́gẹ́ àṣẹ Dafidi ènìyàn Ọlọ́run.

25 Mattaniah, Bakbukiah, Obadiah, Meṣullamu, Talmoni àti Akkubu ni aṣọ́wọ́n ń sọ yàrá ìkó nǹkan pamọ́ ẹnu-ọ̀. 26 Wọ́n ṣiṣẹ́ ìránṣẹ́ ìgbà ayé e Joiakimu ọmọ Jeṣua, ọmọ Josadaki, àti ọjọ́ Nehemiah baálẹ̀ àti ọjọ́ Esra àlùfáà àti akọ̀.

Ìyàsímímọ́ odi Jerusalẹmu

27 Nígbà ìyàsímímọ́ odi Jerusalẹmu a àwọn ọmọ Lefi jáde láti ibi wọ́n ń gbé, wọ́n wọn Jerusalẹmu láti fi ayọ̀ ṣe ayẹyẹ ìyàsímímọ́ pẹ̀orin ìdúpẹ́ àti pẹ̀ohun èlò orin kimbali, haapu àti ohun èlò orin olókùn. 28 A àwọn akọrin náà jọ papọ̀ láti àwọn ìletò ó Jerusalẹmu náà láti àwọn abúlé Netofa, 29 láti Beti-Gilgali, àti láti àwọn agbègbè Geba àti Asmafeti, nítorí àwọn akọrin ti kọ́ àwọn ìletò fúnra wọn agbègbè Jerusalẹmu. 30 Nígbà àwọn àlùfáà àti àwọn ọmọ Lefi ti ya ara wọn mímọ́, wọ́n ya àwọn ènìyàn mímọ́, àti ẹnu ibodè àti odi pẹ̀.

31 Mo tún yan àwọn olórí Juda láti gun orí odi náà. Mo tún yan àwọn ẹgbẹ́ akọrin ńlá méjì láti dúpẹ́. Àwọn kan yóò gòkè odi lọ apá ̀tún ̀ibodè Ààtàn. 32 Hoṣaiah àti ìdajì àwọn olórí Juda tẹ̀wọn, 33 àwọn wọ̀nyí náà lọ pẹ̀wọn, Asariah, Esra, Meṣullamu, 34 Juda, Benjamini, Ṣemaiah, Jeremiah, 35 pẹ̀àwọn àlùfáà díẹ̀ pẹ̀ìpè, pẹ̀u Sekariah ọmọ Jonatani, ọmọ Ṣemaiah, ọmọ Mattaniah, ọmọ Mikaiah, ọmọ Sakkuri, ọmọ Asafu, 36 àti àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀, Ṣemaiah, Asareeli, Milalai, Gilalai, Maai, Netaneli, Juda àti Hananipẹ̀ohun èlò orin àṣẹ Dafidi ènìyàn Ọlọ́run. Esra akọ̀ni ó ṣáájú wọn wọ́n ti ń lọ lọ́wọ̀̀wọ́. 37 ẹnu ibodè orísun wọ́n ti ń lọ tààrà ̀orí àtẹ̀gùn ìlú Dafidi orí òkè ó kángun odi, wọ́n gba ̀gbẹ́ ilé Dafidi kọjá títí ẹnu ibodè omi ìhà ìlà-oòrùn.

38 Àwọn ẹgbẹ́ akọrin kejì gba ̀òdìkejì lọ. Mo tẹ̀wọn orí odi, pẹ̀ìdajì àwọn ènìyàn, kọjá ilé ìṣọ́ ìléru lọ odi fífẹ̀, 39 kọjá ẹnu ibodè Efraimu ibodè Jeṣana, ẹnu ibodè ẹja, ilé ìṣọ́ Hananeli àti ilé ìṣọ́ ọgọ́rùn-ún, títí ẹnu ibodè àgùntàn. Wọ́n dúró ibodè ìṣọ́.

40 Àwọn ẹgbẹ́ akọrin méjèèjì wọ́n dúpẹ́ ààyè nínú ilé Ọlọ́run, èmi náà dúró ààyè mi pẹ̀ìdajì àwọn ìjòyè, 41 àti àwọn àlùfáà Eliakimu, Maaseiah, Miniamini, Mikaiah, Elioenai, Sekariah àti Hananiah pẹ̀àwọn ìpè wọn. 42 Àti pẹ̀Maaseiah, Ṣemaiah, Eleasari àti Ussi, àti Jehohanani, àti Malkiah, àti Elamu, àti Eseri. Àwọn akọrin kọrin sókè abẹ́ alábojútó Jesrahiah. 43 ọjọ́ náà wọ́n ẹbọ ńlá, wọ́n ṣe àjọyọ̀ nítorí Ọlọ́run ti fún wọn ayọ̀ ńlá. Àwọn obìnrin àti àwọn ọmọdé yọ̀ pẹ̀. A gbọ́ ariwo ayọ̀ ó jáde láti Jerusalẹmu jìnnà réré.

44 àkókò náà, a yan àwọn ènìyàn láti jẹ́ alábojútó yàrá ìṣúra fún àwọn ọrẹ àkọ́so èso àti àwọn ìdámẹ́wàá. Láti inú àwọn oko ó àyíká ìlú ni wọ́n ti láti sínú yàrá ìṣúra, ìpín òfin sọ fún àwọn àlùfáà àti àwọn ọmọ Lefi, nítorí inú àwọn ará a Juda yọ́ àwọn àlùfáà àti àwọn ọmọ Lefi ń ṣiṣẹ́ ìránṣẹ́. 45 Wọ́n ń ṣiṣẹ́ Ọlọ́run wọn àti iṣẹ́ ìyàsímímọ́, bẹ́̀ náà ni fún àwọn akọrin àti àwọn aṣọ́, wọ́n ń ṣe gẹ́gẹ́ Dafidi àti Solomoni ọmọ rẹ̀ ti pàṣẹ fún wọn. 46 ọjọ́ pípẹ́ sẹ́yìn ìgbà Dafidi àti Asafu, ni àwọn atọ́nisọ́ti fún àwọn akọrin àti fún orin ìyìn àti orin ọpẹ́ Ọlọ́run. 47 Nítorí náà ìgbà ayé Serubbabeli àti Nehemiah, gbogbo Israẹli ni ó ń ìpín lójoojúmọ́ fún àwọn akọrin àti àwọn aṣọ́. Wọ́n tún yan ìpín mìíràn sọ́tọ̀ fún àwọn ọmọ Lefi tókù, àwọn ọmọ Lefi náà tún ya ìpín ti àwọn ọmọ Aaroni sọ́tọ̀ fún wọn.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também