Pular para o conteúdo
Publicidade

Nehemiah 3

Àwọn ó mọ odi

1 Eliaṣibu olórí àlùfáà àti àwọn àlùfáà arákùnrin rẹ̀ lọ ṣiṣẹ́, wọ́n tún ibodè Àgùntàn mọ. Wọ́n á mímọ́, wọ́n gbé ìlẹ̀kùn dúró ibi ó yẹ, wọ́n mọ ́n títí ilé ìṣọ́ ọgọ́rùn-ún, èyí wọ́n mímọ́ títí ilé ìṣọ́ gíga Hananeli. 2 Àwọn ọkùnrin Jeriko mọ ̀gbẹ́ rẹ̀, Sakkuri ọmọ Imri mọ ̀gbẹ́ àwọn ọkùnrin Jeriko.

3 Àwọn ọkùnrin Senaa ni wọ́n mọ ibodè ẹja. Wọ́n kún ̀pọ̀ ìgbéró rẹ̀, wọ́n gbé ìlẹ̀kùn rẹ̀, ìdábùú ìlẹ̀kùn àti àwọn ìdè e rẹ̀ ààyè e wọn. 4 Meremoti ọmọ Uriah, ọmọ Hakosi tún èyí ó ̀gbẹ́ wọn mọ. Ẹni ó tún ̀gbẹ́ rẹ̀ ni Meṣullamu ọmọ Berekiah, ọmọ Meṣesabeli tún èyí ti ó ̀gbẹ́ wọn mọ. Bákan náà ni ̀gbẹ́ rẹ̀, Sadoku ọmọ Baanah náà tún odi mọ. 5 Èyí ó tún ̀gbẹ́ wọn ni àwọn ọkùnrin Tekoa tún mọ, ṣùgbọ́n àwọn ọlọ́ṣe àtìlẹ́yìn fún iṣẹ́ náà lábẹ́ àwọn olórí wọn.

6 Jehoida ọmọ Pasea àti Meṣullamu ọmọ Besodeiah ni wọ́n tún ẹnu ibodè àtijọ́ ṣe. Wọ́n kún bíìmù rẹ̀, wọ́n ri àwọn ìlẹ̀kùn rẹ̀, àwọn ìdábùú ìlẹ̀kùn àti àwọn ìdè rẹ̀ ààyè wọn. 7 Lẹ́yìn in wọn ni àtúnṣe tún láti ̀dọ̀ àwọn ọkùnrin Gibeoni àti Mispa; Melatiah ti Gibeoni àti Jadoni ti Meronoti; àwọn ibi ó lábẹ́ àṣẹ baálẹ̀ agbègbè Eufurate. 8 Usieli ọmọ Harhiah, ̀kan lára àwọn alágbẹ̀dẹ wúrà, túnṣe àtúnṣe èyí ó lẹ́gbẹ̀́ rẹ̀; àti Hananiah, ̀kan lára àwọn ó ń ṣe tùràrí, túnṣe àtúnṣe èyí ó tún tẹ̀e. Wọ́n Jerusalẹmu padà bọ̀ sípò títí Odi gbígbòòrò. 9 Refaiah ọmọ Huri, alákòóso ìdajì agbègbè Jerusalẹmu, tún èyí ó lẹ́gbẹ̀́ rẹ̀ ṣe. 10 ̀gbẹ́ èyí Jedaiah ọmọ Haramafu tún èyí ó ̀́kán ilé rẹ̀ mọ, Hattusi ọmọ Haṣbneiah tún ̀gbẹ́ rẹ̀ mọ. 11 Malkiah ọmọ Harimu àti Haṣubu ọmọ Pahati-Moabu tún ̀gbẹ́ kejì ṣe àti ilé ìṣọ́ ìléru. 12 Ṣallumu ọmọ Halloheṣi, alákòóso ìdajì agbègbè Jerusalẹmu tún ti ̀gbẹ́ rẹ̀ mọ pẹ̀ìrànlọ́wọ́ àwọn ọmọbìnrin rẹ̀.

13 Ibodè àfonífojì ni Hanuni àti àwọn ará Sanoa tún mọ. Wọ́n tún un kọ́, wọ́n ri àwọn ìlẹ̀kùn àti àwọn ìdè rẹ̀ ààyè rẹ̀. Wọ́n tún tún ẹgbẹ̀rún (1,000) kan ìgbọ̀nwọ́ odi mọ títí ẹnu ibodè ààtàn.

14 Ẹnu ibodè Ààtàn ni Malkiah ọmọ Rekabu, alákòóso agbègbè Beti-Hakeremu tún mọ. Ó tún un mọ, ó gbé àwọn ìlẹ̀kùn rẹ̀, àwọn ìdábùú ìlẹ̀kùn àti àwọn ìdè rẹ̀ ààyè wọn.

15 Ẹnu ibodè orísun ni Ṣalluni Koli-Hose, alákòóso agbègbè Mispa tún mọ. Ó tún ún mọ, ó kan òrùlé e rẹ̀ yíká, ó gbé àwọn ìlẹ̀kùn rẹ̀ àwọn ìdábùú ìlẹ̀kùn àti àwọn idẹ rẹ̀ ààyè wọn. Ó tún tún odi adágún Siloamu mọ, ̀gbẹ́ ọgbà ọba, títí àwọn àtẹ̀gùn ó sọ̀kalẹ̀ lọ láti ìlú Dafidi. 16 Lẹ́yìn in rẹ̀ ni, Nehemiah ọmọ Asbuku, alákòóso ìdajì agbègbè Beti-Suri ṣe àtúnmọ ibi ̀́kán òdìkejì ibojì Dafidi, títí adágún omi àtọwọ́àti títí ilé àwọn alágbára.

17 Lẹ́yìn rẹ̀ ni àwọn ará a Lefi, abẹ́ Rehumu ọmọ Bani. Lẹ́gbẹ̀́ rẹ̀ ni Haṣabiah, alákòóso ìdajì agbègbè Keila ṣe àtúnṣe fún agbègbè tirẹ̀. 18 Lẹ́yìn rẹ̀ ni àwọn Lefi arákùnrin wọn abẹ́ àkóso Binnui ṣe àtúnṣe, Bafai ọmọ Henadadi, ìjòyè àwọn ìdajì agbègbè Keila. 19 Lẹ́yìn rẹ̀ ni Eseri ọmọ Jeṣua, alákòóso Mispa, tún ìbò mìíràn ṣe, láti ibìkan ó kojú ibi gíga ilé-ìhámọ́ra títí orígun. 20 Lẹ́yìn rẹ̀ ni Baruku ọmọ Sakkai fi ìtara tún apá mìíràn ṣe, láti orígun ẹnu-ọ̀ilé Eliaṣibu olórí àlùfáà. 21 Lẹ́yìn rẹ̀ ni, Meremoti ọmọ Uriah, ọmọ Hakosi tún apá mìíràn ṣe, láti ẹnu-ọ̀ilé Eliaṣibu títí òpin rẹ̀.

22 Àtúnṣe a tún túnṣe lẹ́yìn rẹ̀ àwọn àlùfáà àyíká agbègbè túnṣe. 23 Lẹ́yìn wọn ni Benjamini àti Haṣubu tún èyí ti iwájú ilé wọn ṣe; lẹ́yìn wọn ni, Asariah ọmọ Maaseiah ọmọ Ananiah tún ti ̀gbẹ́ ilé rẹ̀ ṣe. 24 Lẹ́yìn rẹ̀ ni Binnui ọmọ Henadadi tún apá mìíràn ṣe, láti ilé Asariah orígun àti kọ̀rọ̀, 25 àti Palali ọmọ Usai tún òdìkejì orígun ṣe àti ilé ìṣọ́ ó yọ sóde láti ibi gíga ̀gbẹ́ ààfin ọba ti òkè lẹ́gbẹ̀́ agbègbè àwọn olùṣọ́. Lẹ́yìn rẹ̀ ni, Pedaiah ọmọ Paroṣi 26 àti àwọn ìránṣẹ́ tẹmpili ó ń gbé òkè Ofeli ṣe àtúnṣe títí ibi ̀kánkán òdìkejì ibodè omi ìhà ìlà-oòrùn àti ilé ìṣọ́ ó yọ sóde. 27 Lẹ́yìn wọn ni àwọn ènìyàn Tekoa tún apá mìíràn ṣe, láti ilé ìṣọ́ ńlá ó yọ sóde títí ògiri Ofeli.

28 Àwọn àlùfáà ni ó ṣe àtúnṣe òkè ibodè ẹṣin ṣe, ẹnìkọ̀̀kan iwájú ilé e rẹ̀. 29 Lẹ́yìn wọn, Sadoku ọmọ Immeri tún ̀kánkán òdìkejì ilé rẹ̀ ṣe. Lẹ́yìn rẹ̀ ni Ṣemaiah ọmọ Ṣekaniah, olùṣọ́ ibodè ìhà ìlà-oòrùn ṣe àtúnṣe. 30 Lẹ́yìn rẹ̀ ni, Hananiah ọmọ Ṣelemiah, àti Hanuni ọmọ ̀kẹfà Salafi, tún apá ibòmíràn ṣe. Lẹ́yìn wọn ni, Meṣullamu ọmọ Berekiah tún ̀kánkán òdìkejì ibùgbé ̀ ṣe. 31 Lẹ́yìn in rẹ̀ ni Malkiah, ̀kan nínú àwọn alágbẹ̀dẹ wúrà ṣe àtúnṣe títí ilé àwọn ìránṣẹ́ tẹmpili àti àwọn oníṣòwò, ̀kánkán òdìkejì ibodè àyẹ̀títí yàrá òkè kọ̀rọ̀; 32 àti láàrín yàrá òkè kọ̀rọ̀ àti ibodè àgùntàn ni àwọn alágbẹ̀dẹ wúrà àti àwọn oníṣòwò túnṣe.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também