Pular para o conteúdo
Publicidade

1 Samuẹli 10

1 Samuẹli ìgò kékeré òróró nínú rẹ̀, ó á orí Saulu. Ó fi ẹnu ó ẹnu, , "Olúwa ha fi òróró yàn olórí lórí ohun ìní rẹ̀? 2 ìwọ kúrò lọ́dọ̀ mi lónìí, ìwọ yóò ọkùnrin méjì pàdé lẹ́bàá ibojì Rakeli Selsa, agbègbè Benjamini. Wọ́n yóò sọ fún , Kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ ìwọ jáde lọ láti wọn . Nísinsin yìí, baba à rẹ dákẹ́ ronú nípa wọn mọ́, ó ń dààmú nípa à rẹ. Ó ń béèrè, "ni èmi yóò ṣe nípa ọmọ mi?" 

3 "Nígbà náà, ìwọ yóò lọ láti ibẹ̀ títí yóò fi ibi igi ńlá Tabori. Ọkùnrin mẹ́ta wọ́n ń gòkè lọ sọ́dọ̀ Ọlọ́run Beteli yóò pàdé rẹ níbẹ̀. ̀kan yóò ọmọ ewúrẹ́ mẹ́ta lọ́wọ́, èkejì, ìṣù àkàrà mẹ́ta àti ̀kẹta yóò ìgò wáìnì. 4 Wọ́n yóò , wọn yóò fún ìṣù àkàrà méjì, ìwọ yóò gbà lọ́wọ́ wọn.

5 "Lẹ́yìn náà, ìwọ yóò lọ òkè Ọlọ́run, níbi ẹgbẹ́ ogun àwọn Filistini . ìwọ ti ń súnmọ́ ìlú náà, ìwọ yóò àwọn wòlíì ó lọ́wọ̀̀wọ́ bọ̀ láti ibi gíga, pẹ̀ohun èlò orin olókùn, tambori àti fèrè àti haapu níwájú wọn, wọn yóò máa sọ àsọtẹ́lẹ̀. 6 ̀Olúwa yóò , ìwọ yóò sọtẹ́lẹ̀ pẹ̀wọn, ìwọ yóò di ẹni ̀tọ̀. 7 ìwọ ti àmì wọ̀nyí, ṣe ohunkóhun ọwọ́ rẹ láti ṣe, nítorí Ọlọ́run pẹ̀rẹ.

8 "Lọ ṣáájú mi Gilgali. Èmi yóò sọ̀kalẹ̀ tọ̀ ́ láti ẹbọ sísun àti láti ẹbọ ìrẹ́pọ̀, ṣùgbọ́n ìwọ gbọdọ̀ dúró fún ọjọ́ méje títí èmi yóò fi ̀dọ̀ rẹ láti sọ fún ohun ó yẹ ìwọ yóò ṣe."

A fi Saulu jẹ ọba

9 Saulu ti yípadà láti fi Samuẹli sílẹ̀, Ọlọ́run ọkàn Saulu padà àti gbogbo àmì wọ̀nyí ìmúṣẹ ọjọ́ náà. 10 Nígbà wọ́n òkè Gibeah náà, àwọn wòlíì ó ń ̀wọ̀̀wọ́ pàdé rẹ̀, ̀Ọlọ́run e nínú agbára, ó darapọ̀ wọ́n sọ àsọtẹ́lẹ̀. 11 Nígbà gbogbo àwọn ó ti mọ̀ ́n tẹ́lẹ̀ i ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ pẹ̀àwọn wòlíì, wọ́n bi ara wọn, "ni ohun ó ti ṣẹlẹ̀ ọmọ Kiṣi yìí. Ṣé Saulu lára àwọn wòlíì ni?"

12 Ọkùnrin kan ó ń gbé níbẹ̀ dáhùn , "Ta ni baba wọn?" Ó ti di ohun a fi ń pa òwe , ǹjẹ́ Saulu náà lára àwọn wòlíì ? 13 Lẹ́yìn Saulu dákẹ́ sísọ àsọtẹ́lẹ̀, ó lọ ibi gíga.

14 Nísinsin yìí, arákùnrin baba Saulu béèrè lọ́wọ́ Saulu àti ìránṣẹ́ rẹ̀ , "Níbo ni lọ?"

Ó , "À ń àwọn kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́," ṣùgbọ́n nígbà a wọn, a lọ ̀dọ̀ Samuẹli.

15 Arákùnrin baba Saulu , "Sọ fún mi ohun Samuẹli fún un yín."

16 Saulu dáhùn , "Ó fi wa lójú wọ́n ti àwọn kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ náà." Ṣùgbọ́n sọ fún arákùnrin baba a rẹ̀ ohun Samuẹli sọ nípa ọba jíjẹ.

17 Samuẹli àwọn ọmọ Israẹli jọ iwájú Olúwa Mispa. 18 Ó fún wọn , "Èyí ni ohun Olúwa Ọlọ́run Israẹli sọ, Èmi Israẹli jáde láti Ejibiti, Èmi gbà yín kúrò lọ́wọ́ agbára Ejibiti àti gbogbo ìjọba ó ń pọ́n ọn yín lójú.19 Ṣùgbọ́n ̀yin ti kọ Ọlọ́run yín, ó gbà yín kúrò nínú gbogbo wàhálà àti ìpọ́njú yín. ̀yin ti sọ , Rárá, yan ọba kan fún wa.Báyìí, ara yín jọ níwájú Olúwa ̀àti ìdílé yín."

20 Nígbà Samuẹli gbogbo ̀Israẹli súnmọ́ tòsí, ó yan ̀Benjamini. 21 Ó ̀Benjamini síwájú ìdílé ìdílé, a yan ìdílé Matiri. ìparí a yan Saulu ọmọ Kiṣi. Ṣùgbọ́n ìgbà wọ́n a, a i, 22 bẹ́̀ ni wọ́n ṣe ìwádìí lọ́wọ́ Olúwa , "Ṣé ọkùnrin náà ti ni?"

Olúwa sọ , "Bẹ́̀ ni ó ti fi ara rẹ̀ pamọ́ láàrín àwọn ẹrù."

23 Wọ́n sáré, wọ́n un jáde . ó ti dúró láàrín àwọn ènìyàn, ó ga ju gbogbo àwọn ó lọ láti èjìká rẹ̀ sókè. 24 Samuẹli sọ fún gbogbo àwọn ènìyàn , "Ṣé ti ri ọkùnrin Olúwa ti yàn? ẹnìkan i rẹ̀ láàrín gbogbo àwọn ènìyàn."

Nígbà náà àwọn ènìyàn kígbe , "̀ọba ó gùn!"

25 Samuẹli ṣàlàyé fún àwọn ènìyàn àwọn ìlànà ìjọba. Ó kọ wọ́n sínú ìwé, ó fi lélẹ̀ níwájú Olúwa. Lẹ́yìn náà, Samuẹli àwọn ènìyàn olúkúlùkù ilé e rẹ̀.

26 Saulu náà padà ilé e rẹ̀ Gibeah. Àwọn akọni ọkùnrin Ọlọ́run ti fi ọwọ́ tọ́ ọkàn wọ́n sìn ín. 27 Ṣùgbọ́n àwọn ọmọ Beliali , "Báwo ni ọkùnrin yìí yóò ti ṣe gbà ?" Wọ́n kẹ́gàn rẹ̀, wọn ̀bùn fún un, ṣùgbọ́n Saulu fọwọ́ lérán.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também