Pular para o conteúdo
Publicidade

1 Samuẹli 31

Saulu pa ara rẹ̀

1 31.1-13: 2Sa 1.6-10; 1Ki 10.1-12. Nísinsin yìí, àwọn ará Filistini dojú ìjà kọ Israẹli, àwọn ará Israẹli sálọ kúrò níwájú wọn, a pa ̀pọ̀ wọn orí òkè Gilboa. 2 Àwọn Filistini ń lépa Saulu àti àwọn ọmọ rẹ̀ kíkan; àwọn Filistini pa Jonatani àti Abinadabu, àti Malikiṣua, àwọn ọmọ Saulu. 3 Ìjà náà burú fún Saulu gidigidi, àwọn tafàtafà si ta á ọfà, o fi ara pa púpọ̀ lọ́wọ́ àwọn tafàtafà.

4 Saulu fún ẹni ó ru ìhámọ́ra rẹ̀ , "Fa idà rẹ yọ, ìwọ fi gún mi, àwọn aláìkọlà wọ̀nyí ba à gún mi, àti wọn ó à fi ṣe ẹlẹ́."

Ṣùgbọ́n ẹni ó ̀ìhámọ́ra rẹ̀ fẹ́ ṣe bẹ́̀, nítorí ̀á gidigidi. Nígbà náà ni Saulu idà, ó ṣubú ú. 5 Nígbà ẹni ó ru ìhámọ́ra rẹ̀ si i Saulu , òun náà fi idà rẹ̀ pa ara rẹ̀, ó pẹ̀rẹ̀. 6 Saulu , àti àwọn ọmọ rẹ̀ mẹ́ta, àti ẹni ó ru ìhámọ́ra rẹ̀, àti gbogbo àwọn ọmọkùnrin rẹ̀ ọjọ́ kan náà.

7 Nígbà ti àwọn ọkùnrin Israẹli ó lápá kejì àfonífojì náà, àti àwọn ẹni ó lápá kejì Jordani, àwọn ọkùnrin Israẹli , àti Saulu àti àwọn ọmọkùnrin rẹ ti , wọ́n fi ìlú sílẹ̀, wọ́n , àwọn Filistini , wọ́n jókòó si ìlú wọn.

8 ọjọ́ kejì, nígbà àwọn Filistini láti bọ́ nǹkan ń bẹ lára àwọn ó , wọ́n , Saulu àti àwọn ọmọ rẹ̀ mẹ́ta ṣubú ni òkè Gilboa. 9 Wọ́n orí rẹ̀, wọ́n bọ ìhámọ́ra rẹ̀, wọ́n ránṣẹ́ lọ ilẹ̀ Filistini káàkiri, láti máa sọ ́ gbangba ni ilé òrìṣà wọn, àti láàrín àwọn ènìyàn. 10 Wọ́n fi ìhámọ́ra rẹ̀ ilé Aṣtoreti: wọ́n kan òkú rẹ̀ mọ́ odi Beti-Ṣani.

11 Nígbà àwọn ará Jabesi Gileadi gbọ́ èyí àwọn Filistini ṣe Saulu. 12 Gbogbo àwọn ọkùnrin alágbára dìde, wọ́n fi gbogbo òru náà rìn, wọ́n gbé òkú Saulu, àti òkú àwọn ọmọ bíbí rẹ̀ kúrò lára odi Beti-Ṣani, wọ́n Jabesi, wọ́n sun wọ́n níbẹ̀. 13 Wọ́n egungun wọn, wọ́n sin wọ́n lábẹ́ igi tamariski Jabesi, wọ́n gbààwẹ̀ ọjọ́ méje.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também