Pular para o conteúdo
Publicidade

1 Samuẹli 22

Dafidi Adullamu àti Mispa

1 Dafidi kúrò níbẹ̀, ó ihò Adullamu; nígbà àwọn arákùnrin rẹ̀ àti ìdílé baba rẹ̀ gbọ́, wọ́n sọ̀kalẹ̀ tọ̀ ́ níbẹ̀. 2 Olúkúlùkù ẹni ó nínú ìpọ́njú, àti olúkúlùkù ẹni ó ti jẹ gbèsè, àti olúkúlùkù ẹni ó nínú ìbànújẹ́, ara wọn jọ sọ́dọ̀ rẹ̀, òun jẹ́ olórí wọn; àwọn ó lọ́dọ̀ rẹ̀ ìwọ̀n irinwó (400) ọmọkùnrin.

3 Dafidi ti ibẹ̀ náà lọ Mispa Moabu: ó fún ọba Moabu , "Jẹ́ baba àti ìyá mi, èmi bẹ̀ ́ gbé, títí èmi yóò fi mọ ohun ti Ọlọ́run yóò ṣe fún mi." 4 Ó wọn síwájú ọba Moabu; wọ́n á gbé gbogbo ọjọ́ Dafidi fi nínú ihò náà.

5 Gadi wòlíì fún Dafidi , "Ma ṣe gbé inú ihò náà, yẹra, o lọ ilẹ̀ Juda." Nígbà náà ni Dafidi yẹra, ó lọ sínú igbó Hereti.

Saulu pa àwọn àlùfáà Nobu

6 Saulu si gbọ́ a Dafidi àti àwọn ọkùnrin ó lọ́dọ̀ rẹ̀; Saulu ń bẹ Gibeah lábẹ́ igi tamariski Rama; ̀kọ̀ rẹ̀ ń bẹ lọ́wọ́ rẹ̀, àti gbogbo àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ dúró í. 7 Nígbà náà ni Saulu fún àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ ó dúró í, , "Ǹjẹ́ gbọ́ ̀yin ará Benjamini, ọmọ Jese yóò ha fún olúkúlùkù yín ni oko ọgbà àjàrà ? ó sọ gbogbo yin olórí ẹgbẹẹgbẹ̀rún àti olórí ̀rọ̀̀rún ? 8 gbogbo yín di ìmọ̀mi, ẹnìkan ó sọ létí mi , ọmọ mi ti ọmọ Jese mulẹ̀, bẹ́̀ ni ẹnìkan nínú yín ó ṣàánú mi, ó sọ ́ létí mi , ọmọ mi ìránṣẹ́ mi dìde mi láti ba , ó ti lónìí."

9 Doegi ará Edomu a fi jẹ olórí àwọn ìránṣẹ́ Saulu, dáhùn , "Èmi ọmọ Jese, ó Nobu, sọ́dọ̀ Ahimeleki ọmọ Ahitubu. 10 Òun béèrè lọ́dọ̀ Olúwa fún un, ó fún un oúnjẹ, ó fún un ni idà Goliati ará Filistini."

11 Ọba ránṣẹ́ pe Ahimeleki àlùfáà, ọmọ Ahitubu àti gbogbo ìdílé baba rẹ̀, àwọn àlùfáà ó ni Nobu: gbogbo wọn ni ó sọ́dọ̀ ọba. 12 Saulu , "Ǹjẹ́ gbọ́, ìwọ ọmọ Ahitubu."

Òun , "Èmi nìyìí olúwa mi."

13 Saulu fún un , "ni ó ̀yin fi ṣọ̀tẹ̀ mi, ìwọ àti ọmọ Jese, ìwọ fi fún un àkàrà, àti idà, àti ti ìwọ fi béèrè fún un lọ́dọ̀ Ọlọ́run òun dìde mi, láti ba , ó ti lónìí."

14 Ahimeleki ọba lóhùn, ó , "Ta ni ó jẹ́ olóòtítọ́ nínú gbogbo àwọn ìránṣẹ́ rẹ Dafidi, ẹni ó jẹ́ àna ọba, ẹni ó ń gbọ́ tìrẹ, ó ni ọlá ilé rẹ. 15 Òní lèmi ó ṣẹ̀ṣẹ̀ máa béèrè lọ́wọ́ Ọlọ́run fún un ? èyí jìnnà mi: ọba ṣe ka nǹkan kan ìránṣẹ́ rẹ̀ lọ́rùn, tàbí gbogbo ìdílé baba mi: nítorí ìránṣẹ́ rẹ̀ mọ̀kan nínú gbogbo nǹkan yìí, díẹ̀ tàbí púpọ̀."

16 Ọba , "Ahimeleki, kíkú ni ìwọ yóò , ìwọ àti gbogbo ìdílé baba rẹ̀."

17 Ọba fún àwọn aṣáájú ti máa ń sáré níwájú ọba, ó dúró í , "Yípadà pa àwọn àlùfáà Olúwa; nítorí ọwọ́ wọn pẹ̀Dafidi, àti nítorí wọ́n mọ ìgbà òun , wọn sọ ́ létí mi."

Ṣùgbọ́n àwọn ìránṣẹ́ ọba jẹ́ fi ọwọ́ wọn àwọn àlùfáà Olúwa láti pa wọ́n.

18 Ọba fún Doegi , "Ìwọ yípadà, o pa àwọn àlùfáà!" Doegi ará Edomu yípadà, ó kọlu àwọn àlùfáà, ó pa wọ́n ọjọ́ náà, àrùnlélọ́gọ́rin ènìyàn ti ń wọ aṣọ ̀gbọ̀ efodu. 19 Ó fi ojú idà pa ara Nobu, ìlú àwọn àlùfáà náà àti ọkùnrin àti obìnrin, ọmọ wẹ́wẹ́, àti àwọn ó lẹ́nu ọmú, àti màlúù, àti kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́, àti àgùntàn.

20 ̀kan nínú àwọn ọmọ Ahimeleki ọmọ Ahitubu a ń Abiatari bọ́; ó àsálà tọ Dafidi lọ. 21 Abiatari fihan Dafidi Saulu pa àwọn àlùfáà Olúwa tán. 22 Dafidi fún Abiatari , "Èmi ti mọ̀ ọjọ́ náà, nígbà Doegi ará Edomu ti níbẹ̀ , nítòótọ́ yóò sọ fún Saulu: nítorí mi ni a ṣe pa gbogbo ìdílé baba rẹ. 23 Ìwọ jókòó níhìn-ín lọ́dọ̀ mi, ṣe bẹ̀, nítorí ẹni ti ń ̀mi, ó ń ̀rẹ, ṣùgbọ́n lọ́dọ̀ mi ni ìwọ ó àìléwu."

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também