Pular para o conteúdo
Publicidade

Esra 5

Lẹ́Tatenai Dariusi

1 5.1: Hg 1.1; Sk 1.1. Nígbà náà wòlíì Hagai àti wòlíì Sekariah, láti ìran Iddo, sọ àsọtẹ́lẹ̀ àwọn ará Júù Juda àti Jerusalẹmu orúkọ Ọlọ́run Israẹli ̀rẹ̀ ń bẹ lára wọn. 2 Nígbà náà Serubbabeli ọmọ Ṣealitieli àti Jeṣua ọmọ Josadaki gbáradì fún iṣẹ́ àti tún ilé Ọlọ́run Jerusalẹmu kọ́. Àwọn wòlíì Ọlọ́run pẹ̀wọn, wọ́n ń ràn wọ́n lọ́wọ́.

3 àkókò náà Tatenai, baálẹ̀ ti agbègbè Eufurate àti Ṣetar-bosnai àti àwọn ẹgbẹgbẹ́ wọn lọ ̀dọ̀ wọn. Wọ́n béèrè , "Ta ni ó fún un yín àṣẹ láti tún tẹmpili yìí kọ́ àti láti tún odi yìí mọ?" 4 Wọ́n tún béèrè , "ni orúkọ àwọn ọkùnrin ó ń kọ́ ilé yìí?" 5 Ṣùgbọ́n ojú Ọlọ́run wọn lára àwọn àgbàgbà Júù, wọn wọn dúró títí ìròyìn yóò fi ̀dọ̀ Dariusi wọ́n gba èsì àkọsílẹ̀ láti ̀dọ̀ rẹ̀.

6 Èyí ni ̀lẹ́Tatenai, olórí agbègbè Eufurate àti Ṣetar-bosnai àti àwọn ẹlẹgbẹ́ wọn. Àwọn olóyè ti agbègbè Eufurate, fi ránṣẹ́ ọba Dariusi. 7 Ìròyìn wọ́n fi ránṣẹ́ i báyìí ,

ọba Dariusi,

Àlàáfíà fún un yín.

8 ọba ó mọ̀ a lọ ̀kún Juda, tẹmpili Ọlọ́run ó tóbi. Àwọn ènìyàn náà ń kọ́ pẹ̀àwọn òkúta ńlá ńlá àti pẹ̀fífi àwọn igi ara ògiri. Wọ́n ṣe iṣẹ́ náà pẹ̀àìsimi, ó ń ìtẹ̀síwájú kíákíá lábẹ́ ìṣàkóso wọn.

9 A bi àwọn àgbàgbà, a fi ̀rọ̀ wọn lẹ́nu , "Ta ni ó fún un yín àṣẹ láti tún ilé Olúwa yìí kọ́ àti láti tún odi rẹ̀ mọ?" 10 A tún béèrè orúkọ wọn pẹ̀, a kọ àwọn orúkọ àwọn olórí wọn sílẹ̀ ba à le mọ ́n.

11 Èyí ni ìdáhùn wọ́n fún wa:

"Àwa ni ìránṣẹ́ Ọlọ́run ̀run àti ayé, àwa ń tún tẹmpili ilé Olúwa a ti kọ́ ̀pọ̀ ọdún sẹ́yìn kọ́, èyí ọba olókìkí kan Israẹli kọ́, ó parí i rẹ̀. 12 Ṣùgbọ́n nítorí àwọn baba wa Ọlọ́run ̀run bínú, ó fi wọ́n Nebukadnessari ti Kaldea, ọba Babeli lọ́wọ́, ẹni ó run tẹmpili Olúwa yìí ó àwọn ènìyàn náà padà Babeli.

13 5.13: Es 1.1; 6.3. "Ṣùgbọ́n ọdún kìn-ín-ní ìjọba Kirusi ọba Babeli, ọba Kirusi pàṣẹ a tún ilé Ọlọ́run yìí kọ́. 14 Òun tilẹ̀ jáde láti inú tẹmpili Babeli fàdákà àti ohun èlò wúrà ilé Ọlọ́run, èyí Nebukadnessari láti inú tẹmpili Jerusalẹmu inú tẹmpili Babeli. Ọba Kirusi wọn fún ọkùnrin kan orúkọ rẹ̀ a máa jẹ́ Ṣeṣbassari, ẹni ó ti yàn gẹ́gẹ́ i baálẹ̀, 15 ó sọ fún un , àwọn ohun èlò yìí o lọ, o wọn inú ilé Olúwa Jerusalẹmu, tún ilé Ọlọ́run kọ́ ipò o rẹ̀.’

16 "Nígbà náà ni Ṣeṣbassari náà , ó fi ìpìlẹ̀ ilé Ọlọ́run ó Jerusalẹmu lélẹ̀, láti ìgbà náà àní títí di ìsinsin yìí ni o ti n bẹ kíkọ́ ṣùgbọ́n, ì parí tán."

17 Nísinsin yìí ó tẹ́ ọba lọ́rùn, jẹ́ a ṣe ìwádìí nínú ìwé ìrántí ilé ìṣúra ọba Babeli láti ọba Kirusi fi àṣẹ lélẹ̀ lóòótọ́ láti tún ilé Ọlọ́run yìí kọ́ Jerusalẹmu. Nígbà náà jẹ́ ọba fi ìpinnu rẹ̀ lórí ̀rọ̀ yìí ránṣẹ́ wa.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também