Pular para o conteúdo
Publicidade

Esra 6

Dariusi ìwé àṣẹ Sairusi

1 Nígbà náà ni ọba Dariusi pàṣẹ, wọ́n inú ilé ìfí nǹkan pamọ́ ilé ìṣúra Babeli. 2 A ìwé kíká kan Ekbatana ibi kíkó ìwé ilé olódi agbègbè Media, wọ̀nyí ni ohun a kọ sínú rẹ̀.

Ìwé ìrántí.

3 6.3: Es 1.1; 5.13. ọdún kìn-ín-ní ìjọba ọba Kirusi, ọba pa àṣẹ kan nípa tẹmpili Ọlọ́run Jerusalẹmu.

Jẹ́ a tún tẹmpili ibi a ti ń onírúurú ẹbọ kọ́, a fi ìpìlẹ̀ rẹ̀ lélẹ̀ ni gíga àti fífẹ̀ rẹ̀ jẹ́ àádọ́rùn-ún ẹsẹ̀ bàtà, 4 pẹ̀ipele òkúta ńlá ńlá mẹ́ta ̀tọ̀̀tọ̀ àti ipele pákó kan, a san owó rẹ̀ láti inú ilé ìṣúra ọba. 5 jẹ́ wúrà àti àwọn ohun èlò fàdákà ti ilé Ọlọ́run, Nebukadnessari láti ilé Olúwa Jerusalẹmu ó lọ Babeli, di dídápadà ààyè wọn nínú tẹmpili Jerusalẹmu; a wọn inú ilé Ọlọ́run.

6 Nítorí náà, ìwọ, Tatenai baálẹ̀ agbègbè Eufurate àti Ṣetar-bosnai àti àwọn ẹlẹgbẹ́ yín, àwọn ìjòyè ti agbègbè náà kúrò níbẹ̀. 7 fi iṣẹ́ ilé Ọlọ́run yìí lọ́rùn sílẹ̀ láì i lọ́wọ́. jẹ́ baálẹ̀ àwọn Júù àti àwọn àgbàgbà Júù tún ilé Ọlọ́run yín kọ́ ipò rẹ̀.

8 Síwájú i, mo pàṣẹ ohun gbọdọ̀ ṣe fún àwọn àgbàgbà Júù wọ̀nyí lórí kíkọ́ ilé Ọlọ́run yìí.

Gbogbo ìnáwó àwọn ọkùnrin yìí ni san lẹ́kùnrẹ́rẹ́ lára ìṣúra ti ọba, láti ibi àkójọpọ̀ owó ìlú ti agbègbè Eufurate iṣẹ́ náà dúró. 9 Ohunkóhun wọ́n fẹ́—àwọn ̀dọ́ akọ màlúù, àwọn àgbò, ̀dọ́-àgùntàn fún ẹbọ sísun Ọlọ́run ̀run, àti jéró, iyọ̀, wáìnì àti òróró, àwọn àlùfáà Jerusalẹmu ti béèrè ni gbọdọ̀ fún wọn lójoojúmọ́ láìyẹ̀. 10 wọn àwọn ẹbọ ó tẹ́ Ọlọ́run ̀run lọ́rùn wọ́n gbàdúrà fún àlàáfíà ọba àti àwọn ọmọ rẹ̀.

11 Síwájú i, mo pàṣẹ ẹnikẹ́ni àṣẹ yìí padà, fa igi àjà ilé rẹ̀ yọ jáde, a gbe dúró, a fi òun náà kọ́ orí rẹ̀ ó wo ilé rẹ̀ palẹ̀ a ó sọ ́ di ààtàn. 12 Ọlọ́run, ó ti jẹ́ orúkọ rẹ̀ máa gbé ibẹ̀, ó pa gbogbo ọba àti orílẹ̀-èdè rún ó gbé ọwọ́ sókè láti àṣẹ yìí padà tàbí láti tẹmpili yìí ó Jerusalẹmu run.

Èmi Dariusi n pàṣẹ rẹ̀, jẹ́ ó di mímúṣẹ láìyí ohunkóhun padà.

Píparí àti yíya tẹmpili mímọ́

13 Nígbà náà, nítorí àṣẹ ọba Dariusi pa, Tatenai, baálẹ̀ ti agbègbè Eufurate, àti Ṣetar-bosnai pẹ̀àwọn ẹlẹgbẹ́ wọn pa á mọ́ láìyí ̀kan padà. 14 Bẹ́̀ ni àwọn àgbàgbà Júù tẹ̀síwájú wọ́n ń gbèrú i lábẹ́ ìwàásù wòlíì Hagai àti wòlíì Sekariah, ìran Iddo. Wọ́n parí kíkọ́ ilé Olúwa gẹ́gẹ́ àṣẹ Ọlọ́run Israẹli àti àwọn àṣẹ Kirusi, Dariusi àti Artasasta àwọn ọba Persia pọ̀. 15 A parí ilé Olúwa ọjọ́ kẹta, oṣù Addari í se oṣù kejì ọdún kẹfà ti ìjọba ọba Dariusi.

16 Nígbà náà ni àwọn ènìyàn Israẹliàwọn àlùfáà, àwọn Lefi àti àwọn ìgbèkùn ó padà, ṣe ayẹyẹ yíya ilé Ọlọ́run mímọ́ pẹ̀ayọ̀. 17 Fún yíya ilé Ọlọ́run yìí mímọ́, wọ́n pa ọgọ́rùn-ún akọ màlúù, igba àgbò àti irinwó (400) akọ ̀dọ́-àgùntàn, àti gẹ́gẹ́ ọrẹ ̀ṣẹ̀ fún gbogbo Israẹli, àgbò méjìlá, ̀kọ̀̀kan fún olúkúlùkù àwọn ̀Israẹli. 18 Wọ́n fi àwọn àlùfáà àwọn ìpín wọ́n àti àwọn Lefi ẹgbẹẹgbẹ́ wọn fún ìsin ti Ọlọ́run Jerusalẹmu, gẹ́gẹ́ ohun a kọ sínú ìwé Mose.

Àjọ ìrékọjá

19 ọjọ́ kẹrìnlá ti oṣù Nisani,6.19 tí ó túmọ̀ sí, oṣù kẹrin àwọn a ìgbèkùn ṣe ayẹyẹ àjọ ìrékọjá. 20 Àwọn àlùfáà àti àwọn ará Lefi ti ya ara wọn mímọ́, wọ́n jẹ́ mímọ́. Àwọn ará Lefi pa ̀dọ́-àgùntàn ti àjọ ìrékọjá fún gbogbo àwọn a ìgbèkùn, fún àwọn àlùfáà arákùnrin wọn àti fún ara wọn. 21 Bẹ́̀ ni àwọn ọmọ Israẹli ó ti láti ìgbèkùn jẹ ́ lápapọ̀ pẹ̀gbogbo àwọn ó ti ya ara wọn kúrò nínú gbogbo iṣẹ́ àìmọ́ ti àwọn kèfèrí aládùúgbò wọn láti Olúwa Ọlọ́run Israẹli. 22 Fún ọjọ́ méje, wọ́n ṣe ayẹyẹ àkàrà àìwú pẹ̀àjẹtì àkàrà. Nítorí Olúwa ti kún wọn pẹ̀ayọ̀ nípa yíyí ọkàn ọba Asiria padà, ó fi ràn wọ́n lọ́wọ́ lórí iṣẹ́ ilé Ọlọ́run, Ọlọ́run Israẹli.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também