Pular para o conteúdo
Publicidade

Esra 4

Àtakò àtúnkọ́ tẹmpili

1 Nígbà àwọn ̀Juda àti Benjamini gbọ́ àwọn ìgbèkùn ó padà ń kọ́ tẹmpili fún Olúwa, Ọlọ́run Israẹli, 2 wọ́n ̀dọ̀ Serubbabeli àti ̀dọ̀ àwọn olórí àwọn ìdílé, wọ́n , "Jẹ́ a a yín kọ́ nítorí , i tiyín, a ń Ọlọ́run yín, a ti ń ẹbọ i láti ìgbà Esarhadoni ọba Asiria, ó wa ibi yìí."

3 Ṣùgbọ́n Serubbabeli, Jeṣua àti ìyókù àwọn olórí àwọn ìdílé Israẹli dáhùn , "ohunkóhun pẹ̀wa kíkọ́ ilé fún Ọlọ́run wa. Àwa nìkan yóò kọ́ fún Olúwa, Ọlọ́run Israẹli, Kirusi, ọba Persia, ti pàṣẹ fún wa."

4 Nígbà náà ni àwọn ènìyàn ilẹ̀ náà ọwọ́ àwọn ènìyàn Juda rọ, wọ́n dẹ́rùbà wọ́n ti kíkọ́ ilé náà. 5 Wọ́n gba àwọn olùdámọ̀ràn láti ṣiṣẹ́ lòdì wọn àti láti sọ ète wọn di asán gbogbo àsìkò ìjọba Kirusi ọba Persia àti títí ìgbà ìjọba Dariusi ọba Persia.

Títako títún Jerusalẹmu kọ́

6 ìbẹ̀rẹ̀ ìjọba Ahaswerusi wọ́n fi ̀sùn kan àwọn ènìyàn Juda àti Jerusalẹmu.

7 Àti àkókò ìjọba Artasasta ọba Persia, Biṣilami, Mitredati, Tabeli àti àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ yòókù kọ̀Artasasta. A kọ ìwé náà ìlànà ìkọ̀Aramaiki èdè Aramaiki a fi kọ ́.

8 Rehumu balógun àti Ṣimṣai akọ̀jùmọ̀ kọ́ ìwé láti dojúkọ Jerusalẹmu Artasasta ọba báyìí:

9 Rehumu balógun àti Ṣimṣai akọ̀, pẹ̀àwọn ẹlẹgbẹ́ wọn tókùàwọn ará Dina, ti Afarsatki, ti Tarpeli, ti Afarsi, Ereki àti Babeli, àwọn ará Elamu ti Susa, 10 pẹ̀àwọn ènìyàn mìíràn ẹni ọlá àti ẹni ̀wọ̀ Asnappari jáde, ó tẹ̀ wọ́n ìlú Samaria àti níbòmíràn agbègbè e Eufurate.

11 (Èyí ni ̀ìwé wọ́n fi ránṣẹ́ i.)

ọba Artasasta,

láti ̀dọ̀ àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀, àwọn ọkùnrin agbègbè Eufurate.

12 Ọba gbọdọ̀ mọ̀ àwọn ará Júù ó gòkè sọ́dọ̀ wa láti ̀dọ̀ rẹ̀ ti lọ Jerusalẹmu wọ́n ń tún ìlú búburú àti ìlú ọlọ̀tẹ̀ kọ́. Wọ́n ń tún àwọn ògiri náà kọ́, wọ́n ń tún àwọn ìpìlẹ̀ náà ṣe.

13 Síwájú i, ọba gbọdọ̀ mọ̀ a kọ́ ìlú yìí àti a tún àwọn ògiri rẹ̀ mọ, owó orí, owó òde tàbí owó ibodè a ó san, owó ó ń wọlé fún ọba yóò dínkù. 14 Nísinsin yìí níwọ̀n ìgbà a ojúṣe ààfin ọba, bójúmu fún wa láti ìtàbùkù ọba, àwa ń rán iṣẹ́ yìí láti sọ fún ọba, 15 a a ṣe ìwádìí inú ìwé ìrántí àwọn aṣíwájú rẹ̀. Nínú ìwé ìrántí wọn yìí, ìwọ yóò i , ìlú yìí jẹ́ ìlú aṣọ̀tẹ̀, oníwàhálà àwọn ọba àti àwọn ìgbèríko, ibi ìṣọ̀tẹ̀ láti ìgbà àtijọ́. Ìdí ni èyí a ṣe pa ìlú yìí run. 16 A fi ọba lójú a tún ìlú kọ́ àti ti àwọn ògiri rẹ̀ si di mímọ padà, yóò ohun ti yóò ́ agbègbè Eufurate.

17 Ọba fi èsì yìí ránṣẹ́ padà.

Rehumu balógun, Ṣimṣai akọ̀àti àwọn ẹlẹgbẹ́ wọn yòókù ń gbé Samaria àti òpópónà Eufurate.

Ìkíni.

18 A ti ka ìwé fi ránṣẹ́ wa, a ti túmọ̀ rẹ̀ níwájú mi. 19 Mo pa àṣẹ, a ṣe ìwádìí, nínú ìtàn ọjọ́ pípẹ́ àti ti ìsinsin yìí ti ìṣọ̀tẹ̀ àwọn ọba pẹ̀, ó jẹ́ ibi ìṣọ̀tẹ̀ àti ìrúkèrúdò. 20 Jerusalẹmu ti àwọn ọba alágbára ń jẹ ọba lórí gbogbo àwọn agbègbè Eufurate, àti àwọn owó orí, owó òde àti owó ibodè ni wọ́n ń san fún wọn. 21 Nísinsin yìí pa àṣẹ fún àwọn ọkùnrin yìí láti iṣẹ́ dúró, a ṣe tún ìlú náà kọ títí èmi yóò fi pàṣẹ. 22 ṣọ́ra ṣe àìkọbi-ara ̀rọ̀ yìí. Èéṣe ìbàjẹ́ yóò fi pọ̀ i, ìpalára àwọn ọba?

23 kété a ka ̀ìwé ọba Artasasta Rehumu àti Ṣimṣai akọ̀àti àwọn ẹlẹgbẹ́ wọn, wọ́n yára lọ ̀dọ̀ àwọn Júù Jerusalẹmu pẹ̀, wọ́n fi agbára wọn láti dáwọ́ dúró.

24 Báyìí, iṣẹ́ lórí ilé Ọlọ́run Jerusalẹmu ìdúró jẹ́́ títí di ọdún kejì ìjọba Dariusi ọba Persia.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também