Pular para o conteúdo
Publicidade

Esra 9

Àdúrà Esra nípa ìgbéyàwó pẹ̀àwọn àjèjì

1 Lẹ́yìn ìgbà a ti ṣe àwọn nǹkan wọ̀nyí tán, àwọn olórí tọ̀ , wọ́n , "Àwọn ènìyàn Israẹli, ó fi mọ́ àwọn àlùfáà àti àwọn ọmọ Lefi, í ya ara wọn sọ́tọ̀ kúrò láàrín àwọn ènìyàn agbègbè wọ́n ń ṣe ohun ìríra i ti àwọn ará Kenaani, àwọn ará Hiti, àwọn ará Peresi, àwọn ará Jebusi, àwọn ará Ammoni, àwọn ará Moabu, àwọn ará Ejibiti àti ti àwọn ará Amori. 2 Wọ́n ti fẹ́ lára àwọn ọmọbìnrin wọn fún ara wọn àti fún àwọn ọmọkùnrin wọn gẹ́gẹ́ aya, wọ́n ti da irú-ọmọ ìran mímọ́ pọ̀ mọ́ àwọn ènìyàn ti ó àyíká wọn. Àwọn olórí àti àwọn ìjòyè ta àwọn ènìyàn tókù yọ nínú híhu ìwà àìṣòótọ́."

3 Nígbà mo gbọ́ èyí, mo fa àwọ̀tẹ́lẹ̀ àti agbádá mi ya, mo tu irun orí àti irùngbọ̀n mi, mo jókòó ìjayà. 4 Nígbà náà ni gbogbo àwọn ó wárìrì ̀rọ̀ Ọlọ́run Israẹli ara wọn jọ mi nítorí àìṣòótọ́ àwọn ìgbèkùn yìí. Èmi jókòó níbẹ̀ ìjayà títí di àkókò ìrúbọ àṣálẹ́.

5 ìgbà ó di àkókò ìrúbọ àṣálẹ́, mo dìde kúrò nínú ìrẹ̀wẹ̀ọkàn mi, pẹ̀àwọ̀tẹ́lẹ̀ àti agbádá mi yíya ọrùn mi, mo kúnlẹ̀ lórí eékún mi méjèèjì, mo tẹ́ ọwọ́ mi méjèèjì Olúwa Ọlọ́run mi. 6 Mo gbàdúrà:

"Ojú gidigidi, n fi gbé ojú mi sókè ̀dọ̀ rẹ, Ọlọ́run mi, nítorí ̀ṣẹ̀ di púpọ̀ orí wa, ̀bi wa ga kan àwọn ̀run. 7 Láti ọjọ́ àwọn baba ni ̀bi wa ti pọ̀ jọjọ títí di ìsinsin yìí. Nítorí ̀ṣẹ̀ wa, àwa àti àwọn ọba wa àti àwọn àlùfáà wa ni a ti sọ di ẹni idà, ẹni ìgbèkùn, ìkógun àti ẹni ̀sín lọ́wọ́ àwọn àjèjì ọba, ó ti lónìí.

8 "Ṣùgbọ́n ni ìsinsin yìí, fún ìgbà díẹ̀, ni a ti fi oore-ọ̀fẹ́ fún wa láti ̀dọ̀ Olúwa Ọlọ́run wa láti sálà, àti láti fi èèkàn fún wa ni ibi mímọ́ rẹ̀, nítorí Ọlọ́run ó ojú wa mọ́lẹ̀, ó tún wa gbé dìde díẹ̀ kúrò nínú ìgbèkùn wa. 9 ó tilẹ̀ jẹ́ àwa jẹ́ ẹrú, Ọlọ́run wa fi wa sílẹ̀ nínú ìgbèkùn wa. Ó ti fi àánú hàn fún wa ni iwájú àwọn ọba Persia: Ó ti fún wa ìgbé ayé tuntun láti tún odi ilé Ọlọ́run wa mọ, a tún àwókù rẹ̀ ṣe, ó fi odi ààbò fún wa Juda àti Jerusalẹmu.

10 "Ṣùgbọ́n nísinsin yìí, Ọlọ́run wa, ni àwa yóò lẹ́yìn èyí? Nítorí àwa kọ àṣẹ rẹ sílẹ̀ 11 èyí ìwọ ti pa fún wa láti ẹnu àwọn wòlíì ìránṣẹ́ rẹ, nígbà ti ìwọ , Ilẹ̀ náà ti ̀yin ń wọ̀ lọ láti gbà n jẹ́ ilẹ̀ aláìmọ́ kún fún ̀gbin àwọn ènìyàn ilẹ̀ náà, nípa ṣíṣe ohun ìríra àti híhu ìwà èérí ti kún ún láti ìkángun kan èkejì. 12 Nítorí náà, ṣe fi àwọn ọmọbìnrin yín fún àwọn ọmọkùnrin wọn ìyàwó tàbí fẹ́ àwọn ọmọbìnrin wọn fún àwọn ọmọkùnrin yín ìyàwó. ṣe májẹ̀àlàáfíà pẹ̀wọn nígbàkígbà ̀yin ó le lágbára, le máa jẹ ire ilẹ̀ náà, le fi í sílẹ̀ fún àwọn ọmọ yín gẹ́gẹ́ ogún ayérayé.

13 "Ohun ó ti ṣẹlẹ̀ wa jẹ́ àyọríṣí iṣẹ́ búburú wa àti ̀bi ̀ṣẹ̀ ńlá wa, síbẹ̀, Ọlọ́run wa, ìjìyà ti ìwọ fún wa kéré si ìjìyà ó yẹ fún ̀ṣẹ̀ ti a , ìwọ fún wa àwọn ènìyàn ṣẹ́èyí. 14 Ǹjẹ́ ó yẹ àwa tún yẹ̀ kúrò nínú àṣẹ rẹ, a máa ṣe ìgbéyàwó papọ̀ pẹ̀àwọn ènìyàn wọn ti ṣe onírúurú ohun ìríra báyìí? Ṣe ìwọ bínú wa láti pa run yóò sẹ́ ku ẹnikẹ́ni yóò ? 15 Ìwọ Olúwa, Ọlọ́run Israẹli, ìwọ jẹ́ olódodo! Àwa ìgbèkùn ó ṣẹ́ó ti lónìí. Àwa dúró níwájú rẹ nínú ̀bi ̀ṣẹ̀ wa, ó tilẹ̀ jẹ́ nítorí èyí ẹnikẹ́ni nínú wa dúró níwájú rẹ".

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também