Pular para o conteúdo
Publicidade

Hagai 2

Ẹwà Tẹmpili tuntun náà

1 ọjọ́ kọkànlélógún oṣù keje, ni ̀rọ̀ Olúwa nípasẹ̀ wòlíì Hagai , 2 "Sọ fún Serubbabeli ọmọ Ṣealitieli, baálẹ̀ Juda, àti Joṣua ọmọ Josadaki, olórí àlùfáà àti àwọn ènìyàn yòókù. Béèrè lọ́wọ́ wọn , 3 Ta ni nínú yín ó ó ti ilé yìí ògo rẹ̀ àkọ́kọ́? Báwo ni ó ṣe ri yín nísinsin yìí? Ǹjẹ́ dàbí asán lójú yín? 4 Ṣùgbọ́n nísinsin yìí, múra gírí, ìwọ Serubbabeli,ni Olúwa . Múra gírí, ìwọ Joṣua ọmọ Josadaki, olórí àlùfáà. múra gírí gbogbo ̀yin ènìyàn ilẹ̀ náà,ni Olúwa , ṣiṣẹ́. Nítorí èmi pẹ̀yín,ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun . 5 Èyí ni ohun Èmi fi a yín májẹ̀nígbà jáde kúrò Ejibiti, bẹ́̀ ni ̀ì mi pẹ̀yín. ṣe bẹ̀.

6 "Báyìí ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun , Láìpẹ́ jọjọ, Èmi yóò mi àwọn ọrun àti ayé, Òkun àti ìyàngbẹ ilẹ̀ lẹ́̀kan i. 7 Èmi yóò mi gbogbo orílẹ̀-èdè, ìfẹ́ gbogbo orílẹ̀-èdè yóò tẹmpili yìí, Èmi yóò kún ilé yìí pẹ̀ògo,ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun . 8 Tèmi ni fàdákà àti wúrà,ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun . 9 Ògo ìkẹyìn ilé yìí yóò pọ̀ ju ti ìṣáájú lọ,ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun , Àti ìhín yìí ni Èmi ó fi àlàáfíà fún ni,ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun ."

Ìbùkún fún àwọn ènìyàn a sọ di àìmọ́

10 ọjọ́ kẹrìnlélógún oṣù kẹsànán ọdún kejì Dariusi, ni ̀rọ̀ Olúwa tọ wòlíì Hagai , 11 "Báyìí ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun , Béèrè lọ́wọ́ àwọn àlùfáà ohun òfin : 12 ẹnìkan gbé ẹran mímọ́ ìṣẹ́aṣọ rẹ̀, ìṣẹ́aṣọ rẹ̀ kan àkàrà tàbí ọbẹ̀, wáìnì, òróró tàbí oúnjẹ mìíràn, ǹjẹ́ yóò ha jẹ́ mímọ́ ?’ "

Àwọn àlùfáà dáhùn , "Bẹ́̀ kọ́."

13 Nígbà náà ni Hagai , "ẹnìkan ó jẹ́ aláìmọ́ nípa fífi ara kan òkú fi ara kan ̀kan lára nǹkan wọ̀nyí, ǹjẹ́ yóò ha jẹ́ aláìmọ́?"

Àwọn àlùfáà dáhùn , "Bẹ́̀ ni, yóò jẹ́ aláìmọ́."

14 Nígbà náà ni Hagai dáhùn ó , " Bẹ́̀ ni ènìyàn wọ̀nyí , bẹ́̀ ni orílẹ̀-èdè yìí níwájú mi,ni Olúwa . Bẹ́̀ ni olúkúlùkù iṣẹ́ ọwọ́ wọn; èyí wọ́n fi ẹbọ níbẹ̀ jẹ́ aláìmọ́.

15 " Ǹjẹ́ nísinsin yìí, ro èyí dáradára láti òní yìí lọ, kíyèsi nǹkan ṣe tẹ́lẹ̀, a to òkúta kan orí èkejì tẹmpili Olúwa. 16 Nígbà ẹnikẹ́ni ibi òkìtì òsùwọ̀n ogun, mẹ́wàá péré ni yóò ba níbẹ̀. Nígbà ẹnikẹ́ni ibi ìfúntí wáìnì láti wọn àádọ́ta ìwọ̀n, ogún péré ni yóò ba níbẹ̀. 17 Mo fi ìrẹ̀dànù, ìmúwòdù àti yìnyín gbogbo iṣẹ́ ọwọ́ yín jẹ; síbẹ̀ ̀yin yípadà ̀dọ̀ mi,ni Olúwa . 18 Láti òní lọ, láti ọjọ́ kẹrìnlélógún oṣù kẹsànán yìí kíyèsi, ó dáradára, ọjọ́ ti a fi ìpìlẹ̀ tẹmpili Olúwa lélẹ̀, ó dáradára. 19 Ǹjẹ́ èso ha nínú abà ? Títí di àkókò yìí, àjàrà àti igi ̀pọ̀tọ́ àti pomegiranate, àti igi olifi ì ì so èso kankan.

" Láti òní lọ ni èmi yóò bùkún fún un yin.’ "

Serubbabeli òrùka èdìdì Olúwa

20 ̀rọ̀ Olúwa tún tọ Hagai nígbà kejì, ọjọ́ kẹrìnlélógún oṣù náà , 21 "Sọ fún Serubbabeli baálẹ̀ Juda èmi yóò mi àwọn ̀run àti ayé. 22 Èmi yóò bi ìtẹ́ àwọn ìjọba ṣubú, Èmi yóò pa agbára àwọn aláìkọlà run, Èmi yóò dojú àwọn kẹ̀kẹ́ ogun , àti àwọn ń gùn wọ́n; ẹṣin àti àwọn ẹlẹ́ṣin yóò ṣubú; olúkúlùkù nípa idà arákùnrin rẹ̀."

23 Olúwa àwọn ọmọ-ogun , "ọjọ́ náà, ìwọ ìránṣẹ́ mi Serubbabeli ọmọ Ṣealitieli, Èmi yóò , Èmi yóò sọ di òrùka èdìdì mi, nítorí mo ti yan , ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun ."

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também

Ageu
Ver todos os capítulos de Ageu