Pular para o conteúdo
Publicidade

Hagai 1

Ìpè láti tún ilé Olúwa kọ́

1 ọdún kejì ọba Dariusi ọjọ́ kìn-ín-ní oṣù kẹfà, ̀rọ̀ Olúwa nípasẹ̀ wòlíì Hagai Serubbabeli ọmọ Ṣealitieli, baálẹ̀ Juda, àti sọ́dọ̀ Joṣua ọmọ Josadaki, olórí àlùfáà.

2 Báyìí ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun : "Àwọn ènìyàn wọ̀nyí , ì àkókò láti kọ́ ilé Olúwa.’ "

3 Nígbà náà ni ̀rọ̀ Olúwa láti ̀dọ̀ wòlíì Hagai , 4 "Ǹjẹ́ àkókò ni fún ̀yin fúnra yín láti máa gbé ilé a ṣe ̀ṣọ́ nígbà ilé yìí ni ahoro?"

5 Nísìnsinyìí, èyí ni ohun Olúwa àwọn ọmọ-ogun : "kíyèsi ̀yín. 6 ̀yin ti gbìn ohun ti ó pọ̀. Ṣùgbọ́n ̀yin kórè díẹ̀ níbẹ̀. ̀yin jẹun, ṣùgbọ́n ̀yin . ̀yin mu ṣùgbọ́n tẹ́ yín lọ́run; ̀yin wọ aṣọ, ṣùgbọ́n òtútù yin lọ; ẹyin gba owó iṣẹ́ ṣùgbọ́n ń gbà á sínú ajádìí àpò."

7 Báyìí ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun : "kíyèsi ̀yín. 8 gun orí àwọn òkè ńlá lọ, igi pẹ̀yín. kọ́ ilé náà, inú mi le è dùn i, a yín lógo," ni Olúwa . 9 "Ẹyin ti ń retí ̀pọ̀, ṣùgbọ́n kíyèsi i, o yípadà díẹ̀. Ohun ̀yin wa ilé, èmi fẹ́ dànù. Nítorí ni?" ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun . "Nítorí ilé mi ó dahoro; olúkúlùkù yín ń sáré fún ilé ara rẹ̀. 10 Nítorí yín ni àwọn ̀run ṣe ìrì dúró ilẹ̀ kọ̀ láti mu èso jáde. 11 Mo ti pe ̀sórí ilẹ̀ àti sórí àwọn òkè ńlá, sórí ọkà àti sórí wáìnì tuntun, sórí òróró àti sórí ohun ti ilẹ̀ ń jáde, sórí ènìyàn, sórí ẹran àti sórí gbogbo iṣẹ́ ọwọ́ yín."

12 Nígbà náà ni Serubbabeli ọmọ Ṣealitieli, Joṣua ọmọ Josadaki, olórí àlùfáà pẹ̀gbogbo ènìyàn ìyókù, gba ohùn Olúwa Ọlọ́run wọn gbọ́ àti ̀rọ̀ wòlíì Hagai, nítorí Olúwa Ọlọ́run ni ó rán an. Àwọn ènìyàn bẹ̀Olúwa.

13 Nígbà náà ni Hagai ìránṣẹ́ Olúwa ń jíṣẹ́ Olúwa fún àwọn ènìyàn , "Èmí pẹ̀yín," ni Olúwa . 14 Nítorí náà, Olúwa ru ̀Serubbabeli ọmọ Ṣealitieli sókè, baálẹ̀ Juda àti ̀Joṣua ọmọ Josadaki, olórí àlùfáà àti ̀gbogbo ènìyàn ìyókù. Wọ́n , wọ́n bẹ̀rẹ̀ ṣiṣẹ́ lórí ilé Olúwa àwọn ọmọ-ogun Ọlọ́run wọn, 15 ọjọ́ kẹrìnlélógún oṣù kẹfà ọdún kejì ọba Dariusi.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também

Ageu
Ver todos os capítulos de Ageu