Pular para o conteúdo
Publicidade

Isaiah 42

Ìránṣẹ́ Olúwa náà

1 42.1-4: Mt 12.18-21. "Ìránṣẹ́ mi nìyìí, ẹni mo gbéró,

àyànfẹ́ mi nínú ẹni mo láyọ̀;

Èmi yóò fi ̀mi sínú rẹ̀

òun yóò ìdájọ́ sórí àwọn orílẹ̀-èdè.

2 Òun yóò pariwo tàbí kígbe sókè,

tàbí ó gbóhùn rẹ̀ sókè òpópónà.

3 Koríko odò títẹ̀ kan ni òun yóò fọ́,

àti òwú-fìtílà ń tan an lọ lòun yóò fẹ́ pa.

òdodo ni yóò ìdájọ́ ;

4 òun yóò kọsẹ̀ bẹ́̀ ni rẹ̀wẹ̀

títí yóò fi fi ìdájọ́ múlẹ̀ ayé.

Nínú òfin rẹ̀ ni àwọn erékùṣù yóò fi ìrètí wọn ."

5 42.5: Ap 17.24-25. Èyí ni ohun Olúwa Ọlọ́run

Ẹni ó àwọn ̀run ó tẹ́ wọ́n sóde,

ó tẹ́ ilẹ̀ ayé àti ohun gbogbo ó jáde nínú wọn,

Ẹni ó fún àwọn ènìyàn rẹ̀ èémí

àti ̀fún gbogbo àwọn ń rìn nínú rẹ̀:

6 42.6: Isa 49.6; Lk 2.32; Ap 13.47; 26.23. "Èmi, Olúwa, ti ́ òdodo,

Èmi yóò di ọwọ́ rẹ .

Èmi yóò pa ́ mọ́, n ó ṣe ́

láti jẹ́ májẹ̀fún àwọn ènìyàn

àti ìmọ́lẹ̀ fún àwọn aláìkọlà

7 42.7,16: Ap 26.18. láti la àwọn ojú ó fọ́,

láti àwọn òǹdè kúrò nínú túbú

àti láti sílẹ̀ kúrò nínú ̀wọ̀n

àwọn ó jókòó nínú òkùnkùn.

8 "Èmi ni Olúwa; orúkọ mi nìyìí!

Èmi yóò fi ògo mi fún ẹlòmíràn

tàbí ìyìn mi fún ère òrìṣà.

9 Kíyèsi i, àwọn nǹkan àtijọ́ ti wáyé,

àti àwọn nǹkan tuntun ni mo ti ;

wọn jáde

mo ti kéde rẹ̀ fún ."

Orin ìyìn Olúwa

10 Kọ orin tuntun Olúwa

ìyìn rẹ̀ láti òpin ilẹ̀ ayé ,

̀yin ó sọ̀kalẹ̀ lọ sínú Òkun, àti ohun gbogbo ń bẹ nínú rẹ̀,

̀yin erékùṣù, àti gbogbo àwọn ń gbé inú wọn.

11 Jẹ́ aginjù àti àwọn ìlú rẹ̀ ó gbé ohùn wọn sókè;

jẹ́ ibùdó ti àwọn ìlú Kedari ń gbé máa yọ̀.

Jẹ́ àwọn ènìyàn Sela kọrin fún ayọ̀;

jẹ́ wọn pariwo láti orí òkè.

12 Jẹ́ wọn fi ògo fún Olúwa

àti wọn kéde ìyìn rẹ̀ erékùṣù.

13 Olúwa yóò rìn jáde gẹ́gẹ́ i ọkùnrin alágbára,

yóò ru owú sókè ológun;

yóò kígbe nítòótọ́, òun yóò igbe ogun,

òun yóò ṣẹ́gun àwọn ̀rẹ̀.

14 "Fún ìgbà pípẹ́ ni mo ti dákẹ́ jẹ́́,

mo ti ìdákẹ́ jẹ́́, mo ara .

Ṣùgbọ́n àkókò yìí, gẹ́gẹ́ obìnrin ó ń rọbí,

mo sọkún, mo ń hẹlẹ hẹlẹ.

15 Èmi yóò sọ òkè ńlá àti kékeré di ahoro

n ó gbẹ gbogbo ewéko rẹ̀ dànù,

Èmi yóò sọ àwọn odò di erékùṣù

n ó gbẹ àwọn adágún.

16 Èmi yóò tọ àwọn afọ́̀wọn ì mọ̀,

ipa ̀ó ṣàjèjì wọn ni èmi yóò tọ́ wọn lọ;

Èmi yóò sọ òkùnkùn di ìmọ́lẹ̀ níwájú wọn

àti ibi pálapàla ni èmi ó sọ di kíkúnná.

Àwọn nǹkan máa ṣe nìyìí;

Èmi yóò kọ̀ wọ́n sílẹ̀.

17 Ṣùgbọ́n àwọn ó gbẹ́kẹ̀òrìṣà,

wọ́n fún ère , ̀yin ni Ọlọ́run wa,

ni a ó padà pẹ̀ìtìjú.

Israẹli fọ́ó dití

18 "Gbọ́, ìwọ adití,

ó, ìwọ afọ́, o !

19 Ta fọ́ṣe ìránṣẹ́ mi,

àti odi gẹ́gẹ́ oníṣẹ́ mo rán?

Ta ni ó fọ́gẹ́gẹ́ ẹni a fi jìnmí,

ó fọ́gẹ́gẹ́ ìránṣẹ́ Olúwa?

20 ̀yin ti ̀pọ̀lọpọ̀ nǹkan, ṣùgbọ́n ṣe àkíyèsí;

etí yín sílẹ̀, ṣùgbọ́n gbọ́ nǹkan kan."

21 Ó dùn mọ́ Olúwa

nítorí òdodo rẹ̀

láti òfin rẹ lágbára àti ògo.

22 Ṣùgbọ́n àwọn ènìyàn kan nìyìí a lógun

a lẹ́,

gbogbo wọn ni ó nínú ̀gbun,

tàbí a fi pamọ́ sínú ̀wọ̀n.

Wọ́n ti di ìkógun,

láìsí ẹnìkan yóò gbà wọ́n sílẹ̀;

wọ́n ti di ìkógun,

láìsí ẹni yóò sọ , "wọn padà."

23 Ta ni nínú yín yóò tẹ́èyí

tàbí ó ṣe àkíyèsí gidi àsìkò ó ń bọ̀?

24 Ta ni ó fi Jakọbu lélẹ̀ fún ìkógun,

àti Israẹli sílẹ̀ fún onísùnmọ̀?

í ha ṣe Olúwa ni,

ẹni àwa ti ṣẹ̀ ?

Nítorí wọn tẹ̀̀rẹ̀;

wọn òfin rẹ̀ ṣẹ.

25 Nítorí náà ni ó ṣe rọ̀ìbínú un rẹ̀ wọn lórí,

rògbòdìyàn ogun.

Èyí ó fi ahọ́n iná wọn po, síbẹ̀ èdè wọn;

ó wọn run, síbẹ̀ wọn fi sọ́kàn wọn rárá.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também