Pular para o conteúdo
Publicidade

Isaiah 48

Israẹli olórí kunkun

1 "Tẹ́èyí, ìwọ ilé e Jakọbu,

ìwọ a ń pẹ̀orúkọ Israẹli

o láti ̀ka Juda,

ìwọ ò ń búra orúkọ Olúwa

o ń pe Ọlọ́run Israẹli

ṣùgbọ́n í ṣe òtítọ́ àti òdodo,

2 ìwọ ò ń pe ara rẹ ọmọ ìlú mímọ́ n

o gbẹ́kẹ̀Ọlọ́run Israẹli

Olúwa àwọn ọmọ-ogun ni orúkọ rẹ̀.

3 Èmi sọ àsọtẹ́lẹ̀ àwọn nǹkan ti tẹ́lẹ̀ lọ́jọ́ ti pẹ́,

ẹnu mi ti kéde wọn, mo sọ wọ́n di mọ̀;

lẹ́yìn náà lójijì mo gbé ìgbésẹ̀, wọ́n ìmúṣẹ.

4 Nítorí mo mọ ti jẹ́ olórí kunkun ;

àwọn iṣan ọrùn yín jẹ́ irin;

bẹ́̀ ni iwájú yín idẹ ni.

5 Nítorí náà mo ti sọ nǹkan wọ̀nyí fún

ọjọ́ ó ti pẹ́;

wọn ó ṣẹlẹ̀ mo ti kéde wọn fún un yín

bẹ́̀ ìwọ fi sọ ,

Àwọn ère mi ṣe wọ́n;

àwọn ère igi àti òrìṣà irin fọwọ́i.

6 Ìwọ ti gbọ́ àwọn nǹkan wọ̀nyí; wo gbogbo wọn.

Ǹjẹ́ o nígbà wọ́n ?

"Láti ìsinsin yìí lọ, Èmi yóò máa sọ

fún nípa nǹkan tuntun,

àwọn nǹkan ó fi ara sin ìwọ mọ̀.

7 A wọn àkókò yìí í ṣe láti ìgbà pípẹ́

ìwọ ì gbọ́ nípa wọn títí di òní.

Nítorí náà, ìwọ sọ ,

Bẹ́̀ ni, mo mọ̀ nípa wọn.

8 Ìwọ a ha ti gbọ́ tàbí ó ti

láti ìgbà àtijọ́ etí ti di yíyà.

Ǹjẹ́ mo mọ̀ o ti jẹ́ alárékérekè ;

a ń ́ ọlọ̀tẹ̀ láti ìgbà ìbí rẹ.

9 Nítorí orúkọ ara mi, mo dáwọ́ ìbínú mi dúró;

nítorí ìyìn ara mi, mo á sẹ́yìn kúrò lọ́dọ̀ rẹ,

a ba à kúrò.

10 ó, èmi ti tún ṣe, ó tilẹ̀ jẹ́

í ṣe i fàdákà;

Èmi ti dán nínú ìléru ìpọ́njú.

11 Nítorí orúkọ mi, nítorí orúkọ mi, mo ṣe èyí.

Báwo ni mo ṣe jẹ́ a ba orúkọ mi jẹ́.

Èmi yóò fi ògo mi fún ẹlòmíràn.

Israẹli dòmìnira

12 48.12: Isa 44.6; If 1.17; 2.8; 22.13. "Tẹ́mi, ìwọ Jakọbu

Israẹli ẹni mo .

Èmi ni ẹni náà;

Èmi ni ẹni àkọ́kọ́ àti ẹni ìgbẹ̀yìn.

13 Ọwọ́ mi pàápàá ni ó fi àwọn ìpìlẹ̀ ayé sọlẹ̀,

àti ọwọ́ ̀tún mi ni ó tẹ àwọn ̀run;

nígbà mo wọ́n,

gbogbo wọn dìde sókè papọ̀.

14 "Gbogbo yín, péjọ gbọ́.

Ta nínú wọn ni ó ti sọ nǹkan wọ̀nyí.

Olúwa ti fẹ́ ,

yóò ṣe ìfẹ́ rẹ̀ Babiloni,

apá rẹ̀ ni yóò ará àwọn ará Kaldea.

15 Èmi, àní Èmi ti sọ̀rọ̀;

bẹ́̀ ni, mo ti é.

Èmi yóò un ,

òun yóò ṣe àṣeyọrí nínú ìrìnàjò rẹ̀.

16 "súnmọ́ ̀dọ̀ mi dẹtí èyí:

"Láti ìgbà ìkéde àkọ́kọ́ èmi sọ̀rọ̀ ìkọ̀kọ̀;

àsìkò ó ṣẹlẹ̀, Èmi níbẹ̀."

Àti àkókò yìí, Olúwa Olódùmarè ni ó ti rán mi,

pẹ̀̀rẹ̀.

17 Èyí ni ohun Olúwa ,

Olùdáǹdè rẹ, Ẹni Mímọ́ Israẹli:

"Èmi ni Olúwa Ọlọ́run rẹ,

ó kọ́ ohun ó dára fún ,

ó tọ́ ṣọ́ó yẹ o máa rìn.

18 ó ṣe ìwọ ti tẹ́sílẹ̀ àṣẹ mi,

àlàáfíà rẹ ti dàbí ì ti odò,

àti òdodo rẹ ìgbì Òkun.

19 Àwọn ọmọ rẹ ìbá ti dàbí iyanrìn,

àwọn ọmọ yín i hóró ọkà a tán;

orúkọ wọn ni a yóò kúrò

tàbí a pa wọ́n run níwájú mi."

20 Fi Babeli sílẹ̀,

fún àwọn ará Babeli,

ṣe ìfilọ̀ èyí pẹ̀ariwo ayọ̀

o kéde rẹ̀.

Rán an jáde lọ òpin ilẹ̀ ayé;

, "Olúwa ti ìránṣẹ́ rẹ̀ Jakọbu nídè."

21 Òrùngbẹ gbẹ wọ́n nígbà ó wọn

kọjá nínú aginjù;

ó jẹ́ omi ó sàn fún wọn láti inú àpáta;

ó fọ́ àpáta

omi jáde.

22 "àlàáfíà," ni Olúwa ,

"Fún àwọn ìkà."

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também