Pular para o conteúdo
Publicidade

Isaiah 2

Òkè Olúwa

1 Èyí ni ohun Isaiah ọmọ Amosi nípa Juda àti Jerusalẹmu.

2 2.2-4: Mt 4.1-3. ìgbẹ̀yìn ọjọ́

òkè tẹmpili Olúwa ni a ó fi ìdí rẹ̀ kalẹ̀

gẹ́gẹ́ olú nínú àwọn òkè,

a ó gbé e ga ju àwọn òkè kéékèèké lọ,

gbogbo orílẹ̀-èdè yóò máa sàn sínú un rẹ̀.

3 ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn ni yóò , wọn yóò ,

", jẹ́ á gòkè ńlá Olúwa,

àti ilé Ọlọ́run Jakọbu.

Òun yóò kọ́ wa ̀rẹ̀,

àwa ó rìn ̀rẹ̀."

Òfin yóò jáde láti Sioni ,

àti ̀rọ̀ Olúwa láti Jerusalẹmu.

4 Òun ó ṣe ìdájọ́ láàrín àwọn orílẹ̀-èdè,

yóò parí aáwọ̀ fún ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ènìyàn.

Wọn yóò fi idà wọn rọ ọkọ́ ìtulẹ̀,

wọn yóò fi ̀kọ̀ wọn rọ dòjé.

Orílẹ̀-èdè yóò gbé idà orílẹ̀-èdè mọ́,

bẹ́̀ wọn yóò kọ́ ogun jíjà mọ́.

5 , ̀yìn ará ilé e Jakọbu,

jẹ́ a rìn nínú ìmọ́lẹ̀ Olúwa.

Ọjọ́ Olúwa

6 Ìwọ ti kọ àwọn ènìyàn rẹ sílẹ̀,

ìwọ ilé Jakọbu.

Wọ́n kún fún ìgbàgbọ́ lẹ́sẹ̀ nílẹ̀ ó ti ìlà-oòrùn ,

wọ́n ń wo iṣẹ́ gẹ́gẹ́ àwọn Filistini,

wọ́n ń pa ọwọ́ pọ̀ pẹ̀àwọn abọ̀rìṣà.

7 Ilẹ̀ wọn kún fún fàdákà àti wúrà,

ìṣúra wọn òpin.

Ilẹ̀ wọn kún fún ẹṣin,

kẹ̀kẹ́ ogun wọn lópin.

8 Ilẹ̀ wọn kún fún ère,

wọ́n ń foríbalẹ̀ fún iṣẹ́ ọwọ́ ara wọn,

èyí ìka ọwọ́ àwọn tìkára wọn ti ṣe.

9 Nítorí náà ni a ó ṣe rẹ ènìyàn sílẹ̀

ìran ọmọ ènìyàn ni yóò di onírẹ̀lẹ̀,

ṣe dáríjì wọ́n.

10 Wọ inú àpáta lọ,

fi ara pamọ́ nínú erùpẹ̀

kúrò nínú ìpayà Olúwa,

àti ògo ọláńlá rẹ̀!

11 Ojú agbéraga ènìyàn ni a ó rẹ̀ sílẹ̀

a ó tẹrí ìgbéraga ènìyàn ba,

Olúwa nìkan ṣoṣo ni a ó gbéga ọjọ́ náà.

12 Olúwa àwọn ọmọ-ogun ọjọ́ kan ìpamọ́

fún gbogbo agbéraga àti ọlọ́kàn gíga

nítorí gbogbo àwọn a gbéga (ni a ó rẹ̀ sílẹ̀),

13 nítorí gbogbo igi kedari Lebanoni, ga rìpó

àti gbogbo óákù Baṣani,

14 nítorí gbogbo òkè gíga ńlá ńlá

àti àwọn òkè kéékèèké,

15 fún ilé ìṣọ́ gíga gíga

àti àwọn odi ìdáàbòbò,

16 fún gbogbo ọkọ̀ àwọn oníṣòwò

àwọn ọkọ̀ a ṣe lọ́ṣọ̀́.

17 Ìgbéraga ènìyàn ni a ó tẹ̀ lórí ba

a ó rẹ ìgbéraga ènìyàn sílẹ̀,

Olúwa nìkan ṣoṣo ni a ó gbéga ọjọ́ náà,

18 gbogbo ère òrìṣà yóò pòórá.

19 Àwọn ènìyàn yóò sálọ sínú ihò àpáta

àti sínú ihò ilẹ̀

kúrò lọ́wọ́ ìpayà Olúwa

àti ògo ọláńlá rẹ̀,

nígbà ó dìde láti mi ayé tìtì.

20 ọjọ́ náà ni àwọn ènìyàn yóò máa sọ

àwọn ère fàdákà àti ère wúrà

wọ́n ti fún bíbọ

èkúté àti àwọn àdán.

21 Wọn yóò sálọ sínú ihò ìsàlẹ̀ àpáta

àti sínú ihò pàlàpálá àpáta

kúrò lọ́wọ́ ìpayà Olúwa

àti ògo ọláńlá rẹ̀,

nígbà ó dìde láti mi ayé tìtì.

22 Dẹ́kun à ń gba ènìyàn gbọ́,

èémí ẹni ihò imú rẹ̀.

Nítorí nínú kín ni a á ?

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também