Pular para o conteúdo
Publicidade

Isaiah 62

Orúkọ Sioni tuntun

1 Nítorí Sioni èmi yóò dákẹ́,

nítorí i Jerusalẹmu èmi yóò sinmi ẹnu,

títí òdodo rẹ̀ yóò fi tàn òwúrọ̀,

àti ìgbàlà rẹ̀ i fìtílà ń geere.

2 62.2: If 2.17. Àwọn orílẹ̀-èdè yóò òdodo rẹ,

àti gbogbo ọba ògo rẹ

a ó máa ́ orúkọ mìíràn

èyí ẹnu Olúwa yóò fi fún un.

3 Ìwọ yóò jẹ́ adé dídán ọwọ́ Olúwa,

adé ọba ọwọ́ Ọlọ́run rẹ.

4 Wọn yóò ́ ìkọ̀sílẹ̀ mọ́

tàbí wọ́n pe ilẹ̀ rẹ ahoro.

Ṣùgbọ́n a ó máa ́ Hẹfsiba,

àti ilẹ̀ rẹ Beula;

nítorí Olúwa yóò yọ́

àti ilẹ̀ rẹ ni a ó gbé níyàwó.

5 Gẹ́gẹ́ ̀dọ́mọkùnrin í gbé ̀dọ́mọbìnrin níyàwó,

bẹ́̀ ni àwọn ọmọkùnrin rẹ yóò gbé níyàwó

Gẹ́gẹ́ ọkọ ìyàwó ṣe é yọ̀ lórí ìyàwó rẹ̀,

bẹ́̀ ni Ọlọ́run rẹ yóò yọ̀ lórí rẹ.

6 Èmi ti fi olùṣọ́ ránṣẹ́ sórí odi rẹ ìwọ Jerusalẹmu;

wọn yóò dákẹ́ tọ̀sán tòru.

̀yin ń pe Olúwa,

ṣe fúnra yín ìsinmi,

7 àti ṣe fún òun pẹ̀ìsinmi

títí yóò fi fi ìdí Jerusalẹmu múlẹ̀

yóò fi ṣe ìyìn orí ilẹ̀ ayé.

8 Olúwa ti búra pẹ̀ọwọ́ ̀tún rẹ̀

àti nípa agbára apá rẹ:

"Èmi yóò jẹ́ ìyẹ̀fun rẹ

di oúnjẹ fún ̀rẹ

bẹ́̀ ni àwọn àjèjì yóò mu wáìnì

tuntun rẹ mọ́

èyí ìwọ ti ṣe làálàá fún;

9 ṣùgbọ́n àwọn ó kóórè rẹ̀ ni yóò jẹ ́,

wọn ó yin Olúwa,

àti àwọn wọ́n àjàrà jọ ni wọn ó un,

nínú àgbàlá ilé mímọ́ mi."

10 kọjá, kọjá ẹnu ibodè náà!

tún ̀ṣe fún àwọn ènìyàn.

mọ ́n sókè, ṣe ojú ̀òpópó!

ṣa òkúta kúrò.

gbé àsíá sókè fún àwọn orílẹ̀-èdè.

11 Olúwa ti ṣe ìkéde

títí òpin ilẹ̀ ayé:

"sọ fún ọmọbìnrin Sioni ,

Kíyèsi i, Olùgbàlà rẹ ń bọ̀!

Kíyèsi i, èrè ń bẹ pẹ̀rẹ̀,

àti ̀san rẹ̀ pẹ̀n tẹ̀e lẹ́yìn.’ "

12 A ó wọ́n Ènìyàn Mímọ́,

ẹni ìràpadà Olúwa;

a ó máa ́ ìwákiri,

ìlú a yóò kọ̀sílẹ̀.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também