Pular para o conteúdo
Publicidade

Isaiah 52

1 52.1: If 21.27. , , ìwọ Sioni,

wọ ara rẹ agbára.

Gbé aṣọ ògo rẹ wọ̀,

ìwọ Jerusalẹmu, ìlú mímọ́ n .

Àwọn aláìkọlà àti aláìmọ́

yóò wọ inú rẹ mọ́.

2 Gbọn eruku rẹ kúrò;

dìde sókè, o gúnwà, ìwọ Jerusalẹmu.

Bọ́ ̀wọ̀n ń bẹ lọ́rùn rẹ kúrò,

ìwọ ̀dọ́mọbìnrin ìgbèkùn Sioni.

3 Nítorí èyí ni ohun Olúwa ,

"̀fẹ́ ni a ́,

láìsanwó ni a ó ́ padà."

4 Nítorí èyí ni ohun Olúwa Olódùmarè .

"ìgbà àkọ́kọ́ àwọn ènìyàn mi sọ̀kalẹ̀

lọ Ejibiti láti gbé;

láìpẹ́ ni Asiria pọ́n wọn lójú.

5 52.5: Ro 2.24. "Àti àkókò yìí, ni mo níbí?" ni Olúwa .

"Nítorí a ti àwọn ènìyàn mi lọ lọ́fẹ̀́,

àwọn ó ń jẹ ọba lórí wọn fi wọ́n ṣẹlẹ́,"

ni Olúwa .

"Àti ọjọọjọ́

orúkọ mi ni asọ̀rọ̀-òdì nígbà gbogbo.

6 Nítorí náà àwọn ènìyàn mi yóò mọ orúkọ mi;

nítorí ọjọ́ náà, wọn yóò mọ̀

, Èmi ni ó ti sọ àsọtẹ́lẹ̀ rẹ̀.

Bẹ́̀ ni, Èmi ni."

7 52.7: Ap 10.36; Ro 10.15; Ef 6.15. Báwo ni ó ṣe dára lórí òkè

ẹsẹ̀ àwọn ó ìyìnrere ayọ̀ ,

wọ́n kéde àlàáfíà,

ó ìyìnrere ,

ó kéde ìgbàlà,

ó sọ fún Sioni ,

"Ọlọ́run rẹ ń jẹ ọba!"

8 Tẹ́sílẹ̀! Àwọn olùṣọ́ rẹ gbé ohùn wọn sókè

wọ́n kígbe papọ̀ fún ayọ̀.

Nígbà Olúwa padà Sioni,

wọn yóò i pẹ̀ojú u wọn.

9 orin ayọ̀ papọ̀,

̀yin ahoro Jerusalẹmu,

nítorí Olúwa ti tu àwọn ènìyàn rẹ̀ nínú,

ó ti ra Jerusalẹmu padà.

10 52.10: Lk 2.30; 3.6. Olúwa yóò ṣí apá mímọ́ rẹ̀ sílẹ̀

ojú gbogbo orílẹ̀-èdè,

àti gbogbo òpin ilẹ̀ ayé yóò

ìgbàlà Ọlọ́run wa.

11 52.11: 2Kọ 6.17. túká, túká, jáde kúrò níhìn-ín yìí!

fọwọ́ kan ohun àìmọ́ kan!

jáde kúrò nínú rẹ̀ di mímọ́,

̀yin ̀ ń gbé ohun èlò Olúwa.

12 Ṣùgbọ́n ̀yin yóò yára kúrò

tàbí sáré lọ;

nítorí Olúwa ni yóò síwájú yín lọ,

Ọlọ́run Israẹli ni yóò ṣe ààbò lẹ́yìn ín yín.

Ìpọ́njú àti ògo ìránṣẹ́ náà

13 Kíyèsi i, ìránṣẹ́ mi yóò hùwà ọlọ́gbọ́n;

òun ni a ó gbé sókè a ó gbéga

a ó gbé e lékè gidigidi.

14 Gẹ́gẹ́ a ti ̀pọ̀lọpọ̀ wọ́n ń bu ọlá fún un

ìwò ojú rẹ ni a ti bàjẹ́ kọjá ti ẹnikẹ́ni àti ìrísí rẹ̀ a ti bàjẹ́ kọjá ohun ènìyàn ń fẹ́.

15 52.15: Ro 15.21. Bẹ́̀ ni yóò ṣe bomirin àwọn orílẹ̀-èdè ,

àwọn ọba yóò pa ẹnu wọn mọ́ nítorí rẹ̀.

Nítorí ohun a sọ fún wọn, wọn yóò i,

àti ohun wọn ì gbọ́, ni yóò wọn.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também