Pular para o conteúdo
Publicidade

Isaiah 5

Orin ọgbà àjàrà náà

1 5.1-7: Mt 21.33-46; Mk 12.1-12; Lk 20.9-19. Èmi yóò kọrin fún ẹni mo fẹ́ràn

orin kan nípa ọgbà àjàrà rẹ̀.

Olùfẹ́ mi ọgbà àjàrà kan

̀gbẹ́ òkè ẹlẹ́lójú.

2 Ó tu ilẹ̀ rẹ̀, ó ṣa òkúta ibẹ̀ kúrò

ó gbin àyànfẹ́ àjàrà i.

Ó kọ́ ilé ìṣọ́ inú rẹ̀

ó ṣe ìfúntí kan síbẹ̀ pẹ̀.

Lẹ́yìn náà, ó ń retí èso àjàrà dáradára,

ṣùgbọ́n èso búburú ni ó ti ibẹ̀ .

3 "ìsinsin yìí ̀yin olùgbé Jerusalẹmu

àti ̀yin ènìyàn Juda

ṣe ìdájọ́ láàrín èmi àti

ọgbà àjàrà mi.

4 Kín ni ó n ò túnṣe ọgbà àjàrà mi.

Ju èyí mo ti ṣe lọ?

Nígbà mo ń èso dáradára,

èéṣe ó fi so kíkan?

5 ìsinsin yìí, èmi yóò fún

ohun n ó ṣe ọgbà àjàrà mi.

Èmi yóò igi inú rẹ̀ kúrò,

a ó pa á run,

Èmi yóò ògiri rẹ̀ lulẹ̀

yóò di ìtẹ̀mọ́lẹ̀.

6 Èmi yóò sọ ́ di ahoro

láì kọ ́ láì ro ó,

̀wọ̀n àti ̀gún ni yóò níbẹ̀.

Èmi yóò pàṣẹ fún kurukuru

láti ṣe rọ̀sórí i rẹ̀."

7 Ọgbà àjàrà Olúwa àwọn ọmọ-ogun

ni ilé Israẹli

àwọn ọkùnrin Juda

ni àyànfẹ́ ọgbà rẹ̀.

Ó retí ìdájọ́ ̀tọ́ ṣùgbọ́n, ìtàjẹ̀ sílẹ̀ ni ó .

Òun ń retí òdodo ṣùgbọ́n ó gbọ́ ẹkún ìpayínkeke.

Ègún àti ìdájọ́

8 Ègbé ni fún àwọn ń kọ́mọ́

ó ń ra ilẹ̀ mọ́lẹ̀

bẹ́̀ ààyè ṣẹ́

ó nìkan gbé lórí ilẹ̀.

9 Olúwa àwọn ọmọ-ogun ti sọ ́ mi létí:

"Ó dájú àwọn ilé ńlá ńlá

yóò di ahoro, àwọn ilé dáradára yóò láìní olùgbé.

10 Ọgbà àjàrà sáré oko mẹ́wàá yóò

ìkòkò wáìnì kan ,

nígbà òsùwọ̀n homeri kan yóò

agbọ̀n irúgbìn kan ."

11 Ègbé ni fún àwọn wọ́n dìde

kùtùkùtù òwúrọ̀

láti lépa ọtí líle,

wọ́n mu ún títí alẹ́ fi lẹ́

títí wọ́n fi gbinájẹ pẹ̀wáìnì.

12 Wọ́n dùùrù àti ohun èlò orin olókùn níbi àsè wọn,

ṣaworo òun fèrè àti wáìnì,

ṣùgbọ́n wọn ka iṣẹ́ Olúwa ,

wọn bọ̀wọ̀ fún iṣẹ́ ọwọ́ rẹ̀.

13 Nítorí náà àwọn ènìyàn mi yóò lọ ìgbèkùn

nítorí òye fún wọn,

ebi ni yóò pa àwọn ọlọ́wọn ;

ẹgbàágbèje wọn ni òǹgbẹ yóò gbẹ.

14 Nítorí náà isà òkú ti ń dátọ́gidigidi,

ó ti ya ẹnu rẹ̀ sílẹ̀ gbagada,

nínú rẹ̀ ni àwọn gbajúmọ̀ àti mẹ̀kúnnù yóò sọ̀kalẹ̀

pẹ̀ọlá àti ògo wọn.

15 Báyìí, ènìyàn yóò di ìrẹ̀sílẹ̀

àti ọmọ ènìyàn ni a sọ di onírẹ̀lẹ̀

ojú agbéraga ni a rẹ̀ sílẹ̀.

16 Ṣùgbọ́n Olúwa àwọn ọmọ-ogun ni a ó gbéga nípa ̀tọ́ rẹ̀,

Ọlọ́run ẹni mímọ́ yóò fi ara rẹ̀ hàn mímọ́ nípa òdodo rẹ̀.

17 Nígbà náà ni àwọn àgùntàn yóò máa jẹ́ ko ibùgbé e wọn,

àwọn ̀dọ́-àgùntàn yóò máa jẹ nínú ahoro àwọn ọlọ́rọ̀.

18 Ègbé ni fún àwọn ń fi ohun asán fa ̀ṣẹ̀,

àti àwọn o dàbí ẹni wọ́n ń fi okùn kẹ̀kẹ́ ̀sìn fa ẹsẹ̀,

19 àwọn ó sọ , "Jẹ́ Ọlọ́run ṣe kíákíá,

jẹ́ ó yára ṣiṣẹ́ rẹ̀ a i,

jẹ́ ó súnmọ́

jẹ́ ètò ẹni mímọ́ Israẹli ó ,

àwa ó le mọ̀ ́n."

20 Ègbé ni fún àwọn ń pe ibi rere, àti rere ibi,

ń fi òkùnkùn ṣe ìmọ́lẹ̀ àti ìmọ́lẹ̀ ṣe òkùnkùn,

ń fi ìkorò ṣe adùn àti adùn ṣe ìkorò.

21 Ègbé ni fún àwọn ó gbọ́n lójú ara wọn

wọ́n jáfáfá lójú ara wọn.

22 Ègbé ni fún àwọn akọni nínú wáìnì mímu

àti àwọn akíkanjú nínú àdàlú ọtí,

23 wọ́n ẹlẹ́bi sílẹ̀ nítorí àbẹ̀tẹ́lẹ̀,

wọn du aláre ̀tọ́.

24 Nítorí náà, gẹ́gẹ́ ahọ́n iná ṣe ń àgékù koríko run

àti koríko ṣe rẹlẹ̀ wẹ̀nínú iná,

bẹ́̀ ni egbò wọn yóò jẹrà

òdodo wọn yóò fẹ́ lọ eruku:

nítorí wọ́n ti kọ òfin Olúwa àwọn ọmọ-ogun sílẹ̀

wọ́n gan ̀rọ̀ Ẹni mímọ́ Israẹli.

25 Nítorí náà, ìbínú Olúwa gbóná si àwọn ènìyàn rẹ̀,

ó ti gbé ọwọ́ rẹ̀ sókè, ó wọ́n bolẹ̀.

Àwọn òkè wárìrì,

òkú wọn dàbí ààtàn àárín ìgboro.

Pẹ̀gbogbo èyí, ìbínú rẹ̀ kúrò,

ṣùgbọ́n ̀wọ́ rẹ̀ jáde síbẹ̀.

26 Yóò gbé ̀págun sókè àwọn orílẹ̀-èdè ó jìnnà,

yóò kọ wọn ó ìpẹ̀kun ilẹ̀.

kíyèsi, wọ́n yóò yára kánkán.

27 ẹni yóò rẹ̀ nínú wọn, tàbí yóò kọsẹ̀,

ẹni yóò tòògbé tàbí yóò sùn;

bẹ́̀ ni àmùrè ̀gbẹ́ wọn yóò ,

bẹ́̀ ni okùn sálúbàtà wọn yóò ja.

28 Àwọn ọfà wọn múná,

gbogbo ọrun wọn le;

pátákò àwọn ẹṣin wọn le òkúta akọ,

àwọn àgbá kẹ̀kẹ́ wọn dàbí ìjì líle.

29 Bíbú wọn dàbí kìnnìún,

wọ́n ẹgbọrọ kìnnìún,

wọ́n ń kọ wọ́n ti di ẹran ọdẹ wọn

wọn gbé e lọ láìsí ẹni yóò gbà á .

30 ọjọ́ náà, wọn yóò e lórí

gẹ́gẹ́ i rírú omi Òkun.

ènìyàn wo ilẹ̀,

yóò òkùnkùn àti ìbànújẹ́;

pẹ̀lúpẹ̀ìmọ́lẹ̀ yóò di òkùnkùn pẹ̀kurukuru rẹ̀.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também