Pular para o conteúdo
Publicidade

Isaiah 23

Àsọtẹ́lẹ̀ kan nípa Tire

1 23.1-18: El 26.1–28.19; Jl 3.4-8; Am 1.9-10; Sk 9.3-4. ̀rọ̀-ìmọ̀ ó kan Tire.

Hu, ìwọ ọkọ̀ ojú omi Tarṣiṣi!

Nítorí a ti pa Tire run

láìsí ilé tàbí èbúté.

Láti ilẹ̀ Saipurọsi ni

̀rọ̀ ti sọ́dọ̀ wọn.

2 Dákẹ́ jẹ́́, ̀yin ènìyàn erékùṣù

àti ̀yin oníṣòwò ti Sidoni,

̀yin àwọn a wẹ Òkun ti sọ dọlọ́rọ̀.

3 Láti orí àwọn omi ńlá

ni irúgbìn ìyẹ̀fun ti ilẹ̀ Ṣihori ti ;

ìkórè ti odò Naili ni owóòná Tire,

òun ti di ibùjókòó ọjà fún àwọn orílẹ̀-èdè.

4 ojú ó ́, ìwọ Sidoni àti ìwọ

àní ìwọ ilé ààbò ti Òkun,

nítorí Òkun ti sọ̀rọ̀.

"Èmi ì ipò ìrọbí tàbí ìbímọ

Èmi ì wo àwọn ọmọkùnrin

tàbí n tọ́ àwọn ọmọbìnrin dàgbà ."

5 Nígbà ̀rọ̀ Ejibiti,

wọn yóò ìpayínkeke nípa

ìròyìn láti Tire.

6 Kọjá Tarṣiṣi;

pohùnréré, ̀yin ènìyàn erékùṣù.

7 Ǹjẹ́ èyí náà ni ìlú àríyá yín,

ògbólógbòó ìlú náà,

èyí ẹsẹ̀ rẹ̀ ti sìn ín lọ

láti lọ tẹ̀ilẹ̀ ó jìnnà réré.

8 Ta gbèrò èyí Tire,

ìlú aládé,

àwọn oníṣòwò ẹni ó jẹ́ ọmọ-aládé

àwọn oníṣòwò wọ́n jẹ́ ìlúmọ̀míká

orílẹ̀ ayé?

9 Olúwa àwọn ọmọ-ogun ti ṣètò rẹ̀,

láti tẹrí ìgbéraga àti ògo rẹ ba

àti láti rẹ gbogbo àwọn ọlọ́

ilé ayé sílẹ̀.

10 Tu ilẹ̀ rẹ gẹ́gẹ́ i ti ipadò odò Ejibiti,

ìwọ ọmọbìnrin Tarṣiṣi,

nítorí ìwọ èbúté mọ́.

11 Olúwa ti na ọwọ́ rẹ̀ jáde orí Òkun

ó àwọn ilẹ̀ ọba wárìrì.

Ó ti pa àṣẹ kan ó kan Kenaani

a pa ilé ààbò rẹ̀ run.

12 Ó , "àríyá fún mọ́,

ìwọ wúńdíá ti Sidoni, a ti tẹ̀ mọ́lẹ̀ báyìí!

"Gbéra, rékọjá lọ Saipurọsi,

níbẹ̀ pẹ̀o yóò ìsinmi."

13 Bojú wo ilẹ̀ àwọn ará Babeli,

àwọn ènìyàn jámọ́ nǹkan kan báyìí.

Àwọn Asiria ti sọ ́ di

ibùgbé àwọn ohun ẹranko aginjù;

wọn ti gbé ilé ìṣọ́ ìtẹ̀gùn wọn sókè,

wọ́n ti odi rẹ̀ ìhòhò

wọ́n ti sọ ́ di ààtàn.

14 Hu, ìwọ ọkọ̀ ojú omi Tarṣiṣi;

wọ́n ti pa odi rẹ̀ run!

15 àkókò náà a ó gbàgbé Tire fún àádọ́rin ọdún, ọjọ́ ayé ọba kan. Ṣùgbọ́n òpin àádọ́rin ọdún wọ̀nyí, yóò ṣẹlẹ̀ Tire gẹ́gẹ́ orin àgbèrè:

16 "dùùrù kan, rìn kọjá láàrín ìlú,

ìwọ àgbèrè a ti gbàgbé;

lu dùùrù dáradára, kọ ̀pọ̀ orin,

a ba à rántí rẹ."

17 23.17: If 17.2. òpin àádọ́rin ọdún náà, Olúwa yóò Tire . Òun yóò padà àyálò rẹ̀ gẹ́gẹ́ panṣágà, yóò máa ṣe òwò rẹ̀ pẹ̀àwọn ilẹ̀ ọba ó ilẹ̀ ayé. 18 Síbẹ̀síbẹ̀ èrè rẹ̀ àti owó iṣẹ́ rẹ̀ ni a ó sọ́tọ̀ fún Olúwa; a wọn pamọ́ tàbí a wọn mọ́wọ́. Ère rẹ̀ ni a ó fi fún àwọn ó ń gbé níwájú Olúwa, fún ̀pọ̀lọpọ̀ oúnjẹ àti aṣọ.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também