Pular para o conteúdo
Publicidade

Jona 4

Jona bínú àánú Olúwa fihàn

1 Ṣùgbọ́n ó ba Jona nínú jẹ́ gidigidi, ó bínú púpọ̀. 2 4.2: El 34.6.Ó gbàdúrà Olúwa, ó , "Èmí bẹ̀ ́, Olúwa, ǹjẹ́ ̀rọ̀ ti mo sọ kọ́ ni èyí nígbà mo ilẹ̀ mi? Nítorí èyí ni mo ṣé sálọ Tarṣiṣi ìṣáájú: nítorí èmi mọ̀ , Ọlọ́run olóore-ọ̀fẹ́ ìwọ, àti aláàánú, O lọ́ra láti bínú, O ṣeun púpọ̀, O ronúpìwàdà ibi náà. 3 Ǹjẹ́ báyìí, Olúwa, èmi bẹ̀ , gba ̀mi kúrò lọ́wọ́ mi nítorí ó sàn fún mi láti ju àti láààyè lọ."

4 Nígbà náà ni Olúwa , "Ìwọ́ ha ni ̀tọ́ láti bínú ?"

5 Jona jáde kúrò ìlú náà, ó jókòó níhà ìlà-oòrùn ìlú náà. Ó pa àgọ́ kan níbẹ̀ fún ara rẹ̀, ó jókòó ni òjìji abẹ́ rẹ̀ títí yóò fi ohun yóò ṣẹlẹ̀ ìlú náà. 6 Olúwa Ọlọ́run pèsè ìtàkùn kan, ó ṣe é ó gòkè sórí Jona; ó ṣe ìji ó lórí; láti gbà á kúrò nínú ìbànújẹ́ rẹ̀. Jona yọ ayọ̀ ńlá nítorí ìtàkùn náà. 7 Ṣùgbọ́n Ọlọ́run pèsè kòkòrò kan nígbà ilẹ̀ mọ́ ọjọ́ kejì, ó jẹ ìtàkùn náà ó rọ. 8 Ó ṣe, nígbà oòrùn yọ, Ọlọ́run pèsè ̀fúùfù gbígbóná ìlà-oòrùn; oòrùn pa Jona lórí bẹ́̀ ó fi rẹ̀ ́. Ó fẹ́ nínú ara rẹ̀ láti , ó , "Ó sàn fún mi láti ju àti láààyè lọ."

9 Ọlọ́run fún Jona , "O ha tọ́ fún láti bínú nítorí ìtàkùn náà?"

Òun , "Mo ni ̀tọ́, o tọ́ fún mi láti bínú títí ikú."

10 Nígbà náà ni Olúwa , "Ìwọ kẹ́dùn ìtàkùn náà, nítorí èyí ìwọ ṣiṣẹ́ fun, ìwọ mu dàgbà; ó jáde òru kan ó ni òru kan. 11 Ṣùgbọ́n Ninefe ̀kẹ́ mẹ́(120,000) ènìyàn nínú rẹ̀, wọn mọ ọwọ́ ̀tún wọn yàtọ̀ ti òsì, àti ̀pọ̀lọpọ̀ ohun ̀sìn pẹ̀. Ṣé èmí ha kẹ́dùn nípa ìlú ńlá náà?"

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também

Jonas
Ver todos os capítulos de Jonas