Pular para o conteúdo
Publicidade

1 Ọba 1

Adonijah fi ara rẹ̀ jẹ Ọba

1 Nígbà Dafidi ọba di arúgbó, ọjọ́ rẹ̀ pọ̀, ara rẹ̀ le è móoru ó tilẹ̀ jẹ́ wọ́n da ̀pọ̀lọpọ̀ aṣọ ó. 2 Nígbà náà ni àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ fún un , "jẹ́ a ̀dọ́mọbìnrin wúńdíá kan ó dúró ti ọba, ó máa tọ́rẹ̀. ó dùbúlẹ̀ àyà rẹ̀ ara ọba olúwa wa móoru."

3 Nígbà náà ni wọ́n lọ jákèjádò ilẹ̀ Israẹli láti ̀dọ́mọbìnrin arẹwà, wọ́n Abiṣagi, ará Ṣunemu, wọ́n un ̀dọ̀ ọba. 4 Ọmọbìnrin náà rẹwà gidigidi; ó ń ṣe ìtọ́ọba, ó ń ṣe ìránṣẹ́ fún un, ṣùgbọ́n ọba a lòpọ̀.

5 Adonijah ẹni ìyá rẹ̀ ń ṣe Haggiti gbé ara rẹ̀ ga, ó , "Èmi yóò jẹ ọba." Ó ṣètò kẹ̀kẹ́ ogun àti àwọn ẹlẹ́ṣin, pẹ̀àádọ́ta ọkùnrin láti máa sáré níwájú rẹ̀. 6 (Baba rẹ̀ á nínú jẹ́ nípa bíbéèrè lọ́wọ́ rẹ̀ , "Èéṣe ìwọ fi hùwà báyìí?" Ó jẹ́ arẹwà ọkùnrin, òun ni a Absalomu.)

7 Adonijah gbèrò pẹ̀Joabu, ọmọ Seruiah àti Abiatari àlùfáà, wọ́n ṣe ìrànlọ́wọ́ fún un. 8 Ṣùgbọ́n Sadoku àlùfáà, Benaiah ọmọ Jehoiada, Natani wòlíì, Ṣimei àti ̀rẹ́ rẹ̀ Rei àti olórí ogun Dafidi ni darapọ̀ mọ́ Adonijah.

9 Nígbà náà ni Adonijah fi àgùntàn àti màlúù àti ẹran ̀sìn ó sanra ẹbọ níbi Òkúta Soheleti ń bẹ lẹ́gbẹ̀́ En-Rogeli. Ó pe gbogbo àwọn arákùnrin rẹ̀, àwọn ọmọ ọba, àti gbogbo àwọn ọkùnrin Juda wọ́n jẹ́ ìránṣẹ́ ọba. 10 Ṣùgbọ́n pe Natani wòlíì tàbí Benaiah tàbí àwọn olórí tàbí Solomoni arákùnrin rẹ̀.

11 Nígbà náà ni Natani béèrè lọ́wọ́ Batṣeba, ìyá Solomoni , "Ǹjẹ́ ìwọ gbọ́ Adonijah, ọmọ Haggiti ti jẹ ọba láìjẹ́ Dafidi olúwa wa mọ̀ i? 12 Ǹjẹ́ nísinsin yìí, jẹ́ èmi gbà ́ ìmọ̀ràn ìwọ ṣe gba ̀rẹ àti ̀ọmọ rẹ Solomoni. 13 Lọ sọ́dọ̀ Dafidi ọba, o fún un , Olúwa mi ọba, ǹjẹ́ ìwọ búra fún ìránṣẹ́ rẹ , "Dájúdájú Solomoni ọmọ rẹ ni yóò jọba lẹ́yìn mi, yóò jókòó lórí ìtẹ́ mi?" Èéṣe nígbà náà Adonijah fi jẹ ọba?14 Níwọ́n ìgbà ìwọ níbẹ̀, o ń ọba sọ̀rọ̀ èmi yóò , láti wádìí ohun o ti sọ."

15 Bẹ́̀ ni Batṣeba lọ ọba inú yàrá rẹ̀, ọba gbó gidigidi níbi Abiṣagi ará Ṣunemu ti ń ṣe ìránṣẹ́ fún ọba. 16 Batṣeba tẹríba, ó kúnlẹ̀ níwájú ọba.

Ọba béèrè , "ni ìwọ ń fẹ́?"

17 Ó fún ọba , "Olúwa mi; ìwọ fúnra rẹ̀ fi Olúwa Ọlọ́run rẹ búra fún ìránṣẹ́ rẹ , Solomoni ọmọ rẹ yóò jẹ ọba lẹ́yìn mi, yóò jókòó lórí ìtẹ́ mi.18 Ṣùgbọ́n nísinsin yìí, Adonijah ti di ọba, ìwọ, ọba olúwa mi mọ̀ nípa rẹ̀. 19 Òun ti fi ̀pọ̀lọpọ̀ màlúù, àti ẹran ó ̀, àti àgùntàn ẹbọ, ó pe gbogbo àwọn ọmọ ọba, àti Abiatari àlùfáà àti Joabu balógun, ṣùgbọ́n pe Solomoni ìránṣẹ́ rẹ. 20 Olúwa mi ọba, ojú gbogbo Israẹli ń bẹ lára rẹ, láti mọ ẹni yóò jókòó lórí ìtẹ́ olúwa mi ọba lẹ́yìn rẹ. 21 ṣe bẹ́̀ nígbà olúwa mi ọba sùn pẹ̀àwọn baba rẹ̀, wọn yóò ka èmi àti Solomoni ẹlẹ́ṣẹ̀."

22 ó ti ń ọba sọ̀rọ̀ lọ́wọ́, Natani wòlíì wọlé. 23 Wọ́n sọ fún ọba , "Natani wòlíì níbí." Ó lọ síwájú ọba, ó wólẹ̀, ó dojúbolẹ̀.

24 Natani , "Ǹjẹ́ ìwọ, olúwa mi ọba, ti sọ Adonijah ni yóò jẹ ọba lẹ́yìn rẹ àti òun ni yóò jókòó lórí ìtẹ́ rẹ? 25 Ó ti sọ̀kalẹ̀ lọ òní, ó ti ẹbọ ̀pọ̀lọpọ̀ màlúù, àti ẹran ọlọ́ràá àti àgùntàn. Ó ti pe gbogbo àwọn ọmọ ọba, balógun àti Abiatari àlùfáà. Nísìnsinyìí, wọ́n ń jẹ, wọ́n ń mu pẹ̀rẹ̀, wọ́n , Adonijah ọba ó pẹ́!’ 26 Ṣùgbọ́n èmi ìránṣẹ́ rẹ, àti Sadoku àlùfáà, àti Benaiah ọmọ Jehoiada, àti Solomoni ìránṣẹ́ rẹ ni . 27 Ṣé nǹkan yìí ni olúwa mi ọba ti ṣe láìjẹ́ àwọn ìránṣẹ́ rẹ mọ ẹni yóò jókòó lórí ìtẹ́ olúwa mi ọba lẹ́yìn rẹ?"

Dafidi fi Solomoni jẹ ọba

28 Nígbà náà ni Dafidi ọba , "Pe Batṣeba wọlé ." Ó síwájú ọba, ó dúró níwájú rẹ̀.

29 Ọba búra , "Dájúdájú Olúwa ti ẹni ó ti gbà kúrò nínú gbogbo wàhálà 30 Lónìí dandan ni èmi yóò gbé ohun mo ti fi Olúwa Ọlọ́run Israẹli búra fún yọ , Solomoni ọmọ rẹ ni yóò jẹ ọba lẹ́yìn mi, àti yóò jókòó lórí ìtẹ́ mi ipò mi."

31 Nígbà náà ni Batṣeba tẹríba, ó kúnlẹ̀ níwájú ọba , "olúwa mi Dafidi ọba ó pẹ́!"

32 Dafidi ọba , "pe Sadoku àlùfáà wọlé fún mi àti Natani wòlíì àti Benaiah ọmọ Jehoiada." Nígbà wọ́n síwájú ọba, 33 ọba fún wọn , "àwọn ìránṣẹ́ olúwa yín pẹ̀yín Solomoni ọmọ mi ó gun ìbáaka mi, un sọ̀kalẹ̀ Gihoni. 34 Níbẹ̀ ni Sadoku àlùfáà àti Natani wòlíì yóò ti fi òróró yàn án ọba lórí Israẹli. fọn fèrè, , Solomoni ọba ó pẹ́!’ 35 Nígbà náà ni gòkè pẹ̀rẹ̀, ó , ó jókòó sórí ìtẹ́ mi, ó jẹ ọba ipò mi. Èmi ti yàn án ọba lórí gbogbo Israẹli àti Juda."

36 Benaiah ọmọ Jehoiada ọba lóhùn , "Àmín! Olúwa Ọlọ́run olúwa mi ọba, kéde rẹ̀ bẹ́̀. 37 Olúwa ti pẹ̀olúwa mi ọba, bẹ́̀ ni ó pẹ̀Solomoni ó ìjọba rẹ̀ pẹ́ ju ìtẹ́ olúwa mi Dafidi ọba lọ!"

38 Nígbà náà ni Sadoku àlùfáà, Natani wòlíì, Benaiah ọmọ Jehoiada, àwọn ará Kereti àti Peleti sọ̀kalẹ̀ wọ́n gbé Solomoni gun ìbáaka Dafidi ọba Gihoni. 39 Sadoku àlùfáà ìwo òróró láti inú àgọ́, ó á Solomoni lórí. Nígbà náà ni wọ́n fọn fèrè, gbogbo àwọn ènìyàn , "Solomoni ọba ó pẹ́!" 40 Gbogbo ènìyàn gòkè tọ̀ ́ lẹ́yìn wọ́n ń fọn ìpè, wọ́n ń yọ ayọ̀ ńlá, bẹ́̀ ilẹ̀ fún ìró wọn.

41 Adonijah àti gbogbo àwọn àlejò ó lọ́dọ̀ rẹ̀ gbọ́ ́ wọ́n ti ń jẹun tán, wọ́n ń gbọ́ ìpè, Joabu , "ìtumọ̀ gbogbo ariwo nínú ìlú yìí?"

42 ó ti ń sọ̀rọ̀ lọ́wọ́, Jonatani ọmọ Abiatari àlùfáà , Adonijah , "Wọlé , ọkùnrin yíyẹ ìwọ gbọdọ̀ ìròyìn rere ."

43 Jonatani dáhùn, ó fún Adonijah , "Lóòótọ́ ni olúwa wa Dafidi ọba, fi Solomoni jẹ ọba. 44 Ọba ti rán Sadoku àlùfáà, Natani wòlíì, Benaiah ọmọ Jehoiada àti àwọn ará Kereti àti Peleti pẹ̀rẹ̀, wọ́n ti gbé e gun ìbáaka ọba, 45 Sadoku àlùfáà àti Natani wòlíì ti fi òróró yàn án ọba Gihoni. Láti ibẹ̀ ni wọ́n ti gòkè pẹ̀ayọ̀, ìlú ń pẹ̀rẹ̀. Èyí ni ariwo ̀yin ń gbọ́. 46 Solomoni ti jókòó lórí ìtẹ́ ìjọba rẹ̀. 47 Àwọn ìránṣẹ́ ọba ti tún láti olúwa wa Dafidi ọba yọ̀, , Ọlọ́run rẹ̀ orúkọ Solomoni lókìkí ju tirẹ̀ lọ àti ìtẹ́ rẹ̀ ó pọ̀ ju tirẹ̀ lọ!Ọba tẹ ara rẹ̀ ba lórí ibùsùn rẹ̀, 48 ọba , Ògo ni fún Olúwa Ọlọ́run Israẹli, ẹni ó ti jẹ́ ojú mi ẹnìkan ó jókòó lórí ìtẹ́ mi lónìí.’ "

49 Nígbà náà ni gbogbo àwọn àlejò ó lọ́dọ̀ Adonijah dìde ìdágìrì, wọ́n túká. 50 Ṣùgbọ́n Adonijah bẹ̀Solomoni, ó lọ, ó di ìwo pẹpẹ . 51 Nígbà náà ni a sọ fún Solomoni , "Adonijah bẹ̀Solomoni ọba, ó di ìwo pẹpẹ , Ó , Jẹ́ ọba Solomoni búra fún mi lónìí , òun yóò fi idà pa ìránṣẹ́ rẹ̀.’ "

52 Solomoni dáhùn , "ó fi ara rẹ̀ hàn láti jẹ́ ẹni ̀wọ̀, irun orí rẹ̀ kan yóò bọ́ sílẹ̀; ṣùgbọ́n a búburú kan ọwọ́ rẹ̀ òun yóò ." 53 Nígbà náà ni Solomoni ọba rán àwọn ènìyàn, wọ́n un sọ̀kalẹ̀ láti ibi pẹpẹ . Adonijah , ó foríbalẹ̀ fún Solomoni ọba, Solomoni , "Lọ ilé rẹ."

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também