Pular para o conteúdo
Publicidade

1 Ọba 12

Israẹli ṣọ̀tẹ̀ Rehoboamu

1 12.1-19: 2Ki 10.1-19. Rehoboamu lọ Ṣekemu, nítorí gbogbo Israẹli ti lọ síbẹ̀ láti fi í jẹ ọba. 2 Nígbà Jeroboamu ọmọ Nebati, ó Ejibiti síbẹ̀ gbọ́, nítorí ó ti kúrò níwájú Solomoni ọba, ó Ejibiti. 3 Bẹ́̀ ni wọ́n ránṣẹ́ Jeroboamu, òun àti gbogbo ìjọ Israẹli lọ sọ́dọ̀ Rehoboamu, wọ́n fún un , 4 "Baba rẹ sọ àjàgà wa di wúwo, ṣùgbọ́n nísinsin yìí, ìsìn baba rẹ̀ ó le, àti àjàgà rẹ̀ ó wúwo, ó fi wa ọrùn ó fẹ́rẹ̀ díẹ̀, àwa yóò sìn ́."

5 Rehoboamu fún wọn , "lọ títí di ọjọ́ mẹ́ta, nígbà náà ni padà tọ̀ ." Àwọn ènìyàn náà lọ.

6 Nígbà náà ni Rehoboamu ọba fi ̀rọ̀ lọ àwọn àgbàgbà ń dúró níwájú Solomoni baba rẹ̀ nígbà ó láààyè. Ó béèrè , "Ìmọ̀ràn wo ni ̀yin yóò gbà láti àwọn ènìyàn wọ̀nyí lóhùn?"

7 Wọ́n a lóhùn , "ìwọ yóò jẹ́ ìránṣẹ́ fún àwọn ènìyàn wọ̀nyí lónìí, o sìn wọ́n, àti o sọ ̀rọ̀ rere wọn nígbà ìwọ ń wọn lóhùn, wọn yóò máa ṣe ìránṣẹ́ rẹ títí láé."

8 Ṣùgbọ́n Rehoboamu kọ ìmọ̀ràn àwọn àgbàgbà fún un, ó fi ̀rọ̀ náà lọ àwọn ọmọdé wọ́n dàgbà pẹ̀rẹ̀, wọ́n ń sìn ín. 9 Ó bi wọ́n , "ni ìmọ̀ràn yín? Báwo ni a ó ṣe àwọn ènìyàn lóhùn, wọ́n fún mi , Ṣé àjàgà baba rẹ fi wa lọ́rùn ó fúyẹ́ díẹ̀’?"

10 Àwọn ọmọdé ó dàgbà pẹ̀rẹ̀ a lóhùn , "Sọ fún àwọn ènìyàn wọ́n fún , Baba rẹ̀ àjàgà wa wúwo ṣùgbọ́n ìwọ ó fúyẹ́ díẹ̀ fún wa; sọ fún wọn , ìka ọwọ́ mi kékeré nípọn ju ̀gbẹ́ baba mi lọ. 11 Baba mi ti gbé àjàgà wúwo e yín; Èmi yóò fi kún àjàgà yín. Baba mi ti fi pàṣán yín, Èmi yóò fi àkéekèe yín."

12 Jeroboamu àti gbogbo àwọn ènìyàn náà sọ́dọ̀ Rehoboamu ọjọ́ kẹta, gẹ́gẹ́ ọba ti , "padà tọ̀ ọjọ́ kẹta." 13 Ọba fi ohùn líle àwọn ènìyàn lóhùn, ó kọ ìmọ̀ràn àwọn àgbàgbà fún un, 14 Ó tẹ̀ìmọ̀ràn àwọn ọmọdé, ó , "Baba sọ àjàgà yín di wúwo, èmi yóò jẹ́ ó wúwo i, baba mi fi pàṣán yín èmi yóò fi àkéekèe yín." 15 Bẹ́̀ ni ọba fi etí ti àwọn ènìyàn, nítorí ̀ràn náà ti ọwọ́ Olúwa láti ̀rọ̀ ó sọ fún Jeroboamu ọmọ Nebati láti ẹnu Ahijah ará Ṣilo ṣẹ.

16 Nígbà gbogbo Israẹli i ọba kọ̀ láti gbọ́ ti àwọn, wọ́n ọba lóhùn ,

"Ìpín wo ni àwa nínú Dafidi,

ìní wo ni àwa nínú ọmọ Jese?

Padà àgọ́ rẹ, ìwọ Israẹli!

Bojútó ilé ara rẹ, ìwọ Dafidi!"

Bẹ́̀ ni àwọn ará Israẹli padà ilé wọn. 17 Ṣùgbọ́n fún ti àwọn ọmọ Israẹli ń gbé nínú ìlú Juda, Rehoboamu jẹ ọba lórí wọn síbẹ̀.

18 Ọba Rehoboamu rán Adoniramu jáde, ẹni ó ìkáwọ́ iṣẹ́ onírúurú, ṣùgbọ́n gbogbo Israẹli sọ ́ òkúta pa. Ọba Rehoboamu, gbìyànjú láti inú kẹ̀kẹ́ rẹ̀ ó sálọ Jerusalẹmu. 19 Bẹ́̀ ni Israẹli ṣọ̀tẹ̀ ilé Dafidi títí di òní yìí.

20 Nígbà gbogbo Israẹli gbọ́ Jeroboamu ti padà , wọ́n ránṣẹ́, wọ́n é àjọ, wọ́n fi jẹ ọba lórí gbogbo Israẹli. ẹnìkan ó tọ ilé Dafidi lẹ́yìn ṣe kìkì ̀Juda nìkan.

21 Nígbà Rehoboamu Jerusalẹmu, ó gbogbo ilé Juda jọ, àti ̀Benjamini; ̀kẹ́ mẹ́sàn-án (180,000) ènìyàn a yàn, wọ́n ń ṣe ológun, láti ilé Israẹli àti láti ìjọba náà padà bọ̀ sọ́dọ̀ Rehoboamu, ọmọ Solomoni.

22 12.22-24: 2Ki 11.1-4. Ṣùgbọ́n ̀rọ̀ Ọlọ́run tọ Ṣemaiah ènìyàn Ọlọ́run , 23 "Sọ fún Rehoboamu, ọmọ Solomoni, ọba Juda àti fún gbogbo ilé Juda àti ti Benjamini, àti fún àwọn ènìyàn tókù , 24 Báyìí ni Olúwa , "ṣe gòkè lọ láti àwọn arákùnrin yín , àwọn ènìyàn Israẹli. olúkúlùkù yín padà ilé rẹ̀, nítorí nǹkan yìí láti ̀dọ̀ mi ni." ’ " Bẹ́̀ ni wọ́n gbọ́ ̀rọ̀ Olúwa, wọ́n tún padà ilé wọn, gẹ́gẹ́ ̀rọ̀ Olúwa.

Ẹgbọrọ màlúù wúrà Beteli àti Dani

25 Nígbà náà ni Jeroboamu kọ́ Ṣekemu òkè Efraimu, ó ń gbé inú rẹ̀. Láti ibẹ̀ ó jáde lọ, ó kọ́ Penieli.

26 Jeroboamu nínú ara rẹ̀ , "Ìjọba náà yóò padà nísinsin yìí ilé Dafidi. 27 àwọn ènìyàn wọ̀nyí gòkè lọ láti ṣe ìrúbọ ilé Olúwa Jerusalẹmu, wọn yóò tún fi ọkàn wọn fún Olúwa wọn, Rehoboamu ọba Juda. Wọn yóò pa , wọn yóò tún padà tọ Rehoboamu ọba Juda lọ."

28 Lẹ́yìn ó ti gba ìmọ̀ràn, ọba ẹgbọrọ màlúù wúrà méjì. Ó fún àwọn ènìyàn , "Ó ti pọ̀fún yín láti máa gòkè lọ Jerusalẹmu. Àwọn Ọlọ́run yín nìyìí, Israẹli, ó yín láti ilẹ̀ Ejibiti ." 29 Ó gbé ̀kan kalẹ̀ Beteli, àti èkejì Dani. 30 Nǹkan yìí di ̀ṣẹ̀; àwọn ènìyàn lọ títí Dani láti sin èyí ó níbẹ̀.

31 Jeroboamu kọ́ ojúbọ sórí ibi gíga, ó yan àwọn àlùfáà láti inú àwọn ènìyàn ó tilẹ̀ jẹ́ wọn í ṣe inú àwọn ọmọ Lefi. 32 Jeroboamu àsè sílẹ̀ ọjọ́ kẹ́̀dógún oṣù kẹjọ gẹ́gẹ́ àsè ó Juda, ó ẹbọ lórí pẹpẹ. Ó ṣe èyí Beteli, ó ẹbọ àwọn ọmọ màlúù ó ṣe. Ó fi àwọn àlùfáà ibi gíga ó ti ṣe Beteli. 33 ọjọ́ kẹ́̀dógún oṣù kẹjọ, oṣù ó ọkàn ara rẹ̀, ó ẹbọ lórí pẹpẹ ó kọ́ Beteli. Bẹ́̀ ni ó àsè sílẹ̀ fún àwọn ọmọ Israẹli, ó gun orí pẹpẹ náà lọ láti ẹbọ.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também