Pular para o conteúdo
Publicidade

1 Ọba 9

Olúwa farahan Solomoni

1 9.1-9: 2Ki 7.11-22. Nígbà Solomoni parí kíkọ́ ilé Olúwa àti ààfin ọba, ó ti ṣe gbogbo nǹkan ó ń fẹ́ láti ṣe, 2 Olúwa farahàn Solomoni ìgbà kejì, ó ti farahàn án Gibeoni. 3 Olúwa fún un ,

"Èmi ti gbọ́ àdúrà rẹ àti ̀bẹ̀ rẹ ìwọ ti bẹ̀ níwájú mi, mo ti ya ilé yìí mímọ́, ìwọ ti kọ́, nípa fífi orúkọ mi síbẹ̀ títí láé. Ojú mi àti ọkàn mi yóò níbẹ̀ nígbà gbogbo.

4 "ìwọ rìn níwájú mi ọkàn òtítọ́ àti ìdúró ṣinṣin, i Dafidi baba rẹ ti rìn, o ṣe gbogbo èyí mo ti paláṣẹ fún àti o pa àṣẹ mi àti òfin mi mọ́, 5 Èmi yóò fi ìdí ìtẹ́ ìjọba rẹ múlẹ̀ lórí Israẹli títí láé, mo ti ṣe ìlérí fún Dafidi baba rẹ nígbà mo , Ìwọ yóò kùnà láti ọkùnrin kan lórí ìtẹ́ Israẹli.

6 "Ṣùgbọ́n ìwọ tàbí àwọn ọmọ rẹ yípadà kúrò lọ́dọ̀ mi, pa òfin mi mọ́ àti àṣẹ mi mo ti fi fún , lọ láti sin ọlọ́run mìíràn, ń sìn wọ́n, 7 nígbà náà ni èmi yóò Israẹli kúrò ilẹ̀ èmi fi fún wọn, èmi yóò kọ ilé yìí èmi ti mímọ́ fún orúkọ mi. Nígbà náà ni Israẹli yóò di òwe àti ìmúṣẹ̀sín láàrín gbogbo orílẹ̀-èdè. 8 Àti ilé yìí ó ga, ẹnu yóò ya olúkúlùkù ẹni ó kọjá lẹ́bàá rẹ̀, yóò pòṣé, wọn ó , Èéṣe Olúwa fi ṣe irú nǹkan yìí ilẹ̀ yìí àti ilé yìí?9 Àwọn ènìyàn yóò dáhùn , Nítorí wọ́n ti kọ̀ Olúwa Ọlọ́run wọn sílẹ̀, ó àwọn baba wọn jáde láti Ejibiti , wọ́n ti gbá ọlọ́run mìíràn , wọ́n ń bọ wọ́n, wọ́n ń sìn wọ́n, ìdí nìyìí Olúwa ṣe gbogbo ìjàǹbá yìí sórí wọn.’ "

Ojúṣe Solomoni mìíràn

10 Lẹ́yìn ogún ọdún, nígbà Solomoni kọ́ ilé méjèèjì yìí tan: ilé Olúwa àti ààfin ọba. 11 Solomoni ọba fi ogún ìlú Galili fún Hiramu ọba Tire, nítorí Hiramu ti a igi kedari àti igi firi àti wúrà gẹ́gẹ́ gbogbo ìfẹ́ rẹ̀. 12 Ṣùgbọ́n nígbà Hiramu jáde láti Tire lọ wo ìlú Solomoni fi fún un, inú rẹ̀ dùn wọn. 13 Ó , "Irú ìlú wo nìwọ̀nyí ìwọ fi fún mi, arákùnrin mi?" Ó wọ́n ilẹ̀ Kabulu títí fi di òní yìí. 14 Hiramu ti fi ọgọ́tálẹ́ǹtì wúrà ránṣẹ́ ọba.

15 Ìdí àwọn asìnrú ti Solomoni ọba kójọ ni èyí; láti kọ́ ilé Olúwa àti ààfin òun tìkára rẹ̀; Millo, odi Jerusalẹmu, Hasori, Megido àti Geseri. 16 Farao ọba Ejibiti ti kọlu Geseri, ó ti fi iná sun ún, ó pa àwọn ará Kenaani ń gbé ìlú náà, ó fi ta ọmọbìnrin rẹ̀, aya Solomoni lọ́rẹ. 17 Solomoni tún Geseri kọ́, àti Beti-Horoni ìsàlẹ̀, 18 àti Baalati àti Tadmori aginjù, láàrín rẹ̀, 19 àti gbogbo ìlú ìṣúra Solomoni , àti ìlú kẹ̀kẹ́ rẹ̀, àti ìlú fún àwọn ẹlẹ́ṣin rẹ̀, àti èyí ó ń fẹ́ láti kọ́ Jerusalẹmu, Lebanoni àti gbogbo ilẹ̀ ìjọba rẹ̀ ó ń ṣe àkóso.

20 Gbogbo ènìyàn ó nínú àwọn ará Amori ará Hiti, Peresi, Hifi àti Jebusi, àwọn ènìyàn wọ̀nyí í ṣe ará Israẹli, 21 ìyẹn ni àwọn ọmọ wọn ó ilẹ̀ náà, àwọn ọmọ Israẹli le parun pátápátá, àwọn ni Solomoni bu iṣẹ́ ẹrú fún títí di òní yìí. 22 Ṣùgbọ́n, Solomoni fi ẹnìkankan ṣe ẹrú nínú àwọn ọmọ Israẹli; àwọn ni ológun rẹ̀ àti àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀, àti àwọn ìjòyè rẹ̀, àti àwọn balógun rẹ̀, àti àwọn olórí kẹ̀kẹ́ rẹ̀ àti ti àwọn ẹlẹ́ṣin rẹ̀. 23 Àwọn tún ni àwọn olórí olùtọ́wọ́n lórí iṣẹ́ Solomoni, àádọ́ta dín lẹ́gbẹ̀ta (550), ń ṣe àkóso lórí àwọn ènìyàn ń ṣe iṣẹ́ náà.

24 Lẹ́yìn ìgbà ọmọbìnrin Farao ti gòkè láti ìlú Dafidi ààfin Solomoni kọ́ fún un, nígbà náà ni ó kọ́ Millo.

25 Nígbà mẹ́ta lọ́dún ni Solomoni ń ẹbọ sísun àti ẹbọ àlàáfíà lórí pẹpẹ ó tẹ́ fún Olúwa, ó sun tùràrí níwájú Olúwa pẹ̀wọn, bẹ́̀ ni ó parí ilé náà.

26 Solomoni ọba túnṣe òwò ọkọ̀ Esioni-Geberi, ó ̀Elati Edomu, létí Òkun Pupa. 27 Hiramu rán àwọn ènìyàn rẹ̀, àwọn atukọ̀ ó mọ Òkun, pẹ̀àwọn ìránṣẹ́ Solomoni. 28 Wọ́n Ofiri, wọ́n irinwó ó ogún (420) tálẹ́ǹtì wúrà, wọ́n ti gbà fún Solomoni ọba.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também