Pular para o conteúdo
Publicidade

1 Ọba 10

Ayaba Ṣeba bẹ Solomoni

1 10.1-29: 2Ki 9.1-28. Nígbà ayaba Ṣeba gbọ́ òkìkí Solomoni àti ì ṣe pọ̀ rẹ̀ ti orúkọ Olúwa, ó láti dán an pẹ̀ìbéèrè líle. 2 Ó Jerusalẹmu pẹ̀ẹgbẹ́ èrò ńlá ńlá, pẹ̀ìbákasẹ ó ru tùràrí, àti ̀pọ̀lọpọ̀ wúrà, àti òkúta iyebíye, ó ̀dọ̀ Solomoni, ó a sọ gbogbo èyí ń bẹ ọkàn rẹ̀. 3 Solomoni dáhùn gbogbo ìbéèrè rẹ̀; èyí ó ṣòro fún ọba láti ṣàlàyé fún un. 4 Nígbà ayaba Ṣeba gbogbo ọgbọ́n Solomoni àti ààfin ó ti kọ́. 5 Oúnjẹ ó lórí i tábìlì rẹ̀, ìjókòó àwọn ọmọ ̀dọ̀ rẹ̀, àti ìdúró àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ àti ìwọṣọ wọn, àwọn agbọ́rẹ̀, àti ẹbọ sísun ó sun ilé Olúwa, ̀kan nínú rẹ̀ mọ́!

6 Ó fún ọba , "Òtítọ́ ni ìròyìn mo gbọ́ orílẹ̀-èdè mi ti iṣẹ́ rẹ àti ọgbọ́n rẹ. 7 Ṣùgbọ́n èmi gba nǹkan wọ̀nyí gbọ́ títí ìgbà mo , mo fi ojú ara mi i. kíyèsi i, a sọ ìdajì wọn fún mi; ìwọ ti fi ọgbọ́n àti ìrora kọjá òkìkí mo gbọ́. 8 Báwo ni inú àwọn ènìyàn rẹ yóò ṣe dùn ! Báwo ni inú dídùn àwọn ìránṣẹ́ rẹ, wọ́n ń dúró níwájú rẹ nígbà gbogbo, wọ́n ń gbọ́ ọgbọ́n rẹ! 9 Ìbùkún ni fún Olúwa Ọlọ́run rẹ, ó inú dídùn , ó gbé ka orí ìtẹ́ Israẹli. Nítorí Olúwa fẹ́ràn Israẹli títí láé, ni ó ṣe fi ́ jẹ ọba, láti ṣe ìdájọ́ àti òdodo."

10 Ó fún ọba ọgọ́tálẹ́ǹtì wúrà, tùràrí olóòórùn dídùn lọ́pọ̀lọ́pọ̀, àti òkúta iyebíye. irú ̀pọ̀lọpọ̀ tùràrí a ó dàbí irú èyí ayaba Ṣeba fi fún Solomoni ọba.

11 (Pẹ̀lúpẹ̀àwọn ̀wọ́-ọkọ̀ Hiramu ó wúrà láti Ofiri , wọ́n igi algumu lọ́pọ̀lọ́pọ̀ àti òkúta oníyebíye láti Ofiri . 12 Ọba fi igi algumu náà ṣe òpó fún ilé Olúwa àti fún ààfin ọba, àti láti ṣe dùùrù pẹ̀àti ohun èlò orin olókùn fún àwọn akọrin. Irú igi algumu bẹ́̀ mọ́, bẹ́̀ ni a wọn títí di òní yìí.)

13 Solomoni ọba fún ayaba Ṣeba gbogbo ìfẹ́ rẹ̀ àti ohun ó béèrè, yàtọ̀ èyí a fi fún un láti ọwọ́ Solomoni ọba wa. Nígbà náà ni ó yípadà, ó lọ ìlú rẹ̀, pẹ̀àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀.

̀rọ̀ Solomoni

14 Ìwọ̀n wúrà Solomoni ń gbà ọdún kan jẹ́ ̀tàlélẹ́gbẹ̀ta ó mẹ́(666) tálẹ́ǹtì wúrà, 15 láìka èyí ó ń gbà lọ́wọ́ àwọn ajẹ́lẹ̀ àti àwọn oníṣòwò, àti ti gbogbo àwọn ọba Arabia, àti àwọn baálẹ̀ ilẹ̀.

16 Solomoni ọba ṣe igba asà wúrà lílù; ẹgbẹ̀ta (600) ṣékélì wúrà ni ó lọ asà kan. 17 Ó túnṣe ̀́dúnrún (300) asà wúrà lílù, pẹ̀òsùwọ̀n wúrà mẹ́ta ó tàn asà kọ̀̀kan. Ọba wọn ilé igbó Lebanoni.

18 Nígbà náà ni ọba ṣe ìtẹ́ eyín erin ńlá kan, ó fi wúrà dídára ó. 19 Ìtẹ́ náà àtẹ̀gùn mẹ́, ̀yìn rẹ̀ ṣe róbótó lókè. ibi ìjókòó méjèèjì náà ni ìrọpá , pẹ̀kìnnìún ó dúró lẹ́gbẹ̀́ ̀kọ̀̀kan wọn. 20 Kìnnìún méjìlá dúró níbi àtẹ̀gùn mẹ́fẹ̀̀, ̀kọ̀̀kan òpin àtẹ̀gùn kọ̀̀kan, ì irú rẹ̀ ìjọba kan . 21 Gbogbo ohun èlò mímu Solomoni ọba jẹ́ wúrà àti gbogbo ohun èlò ààfin igbó Lebanoni jẹ́ kìkì wúrà. nǹkan kan a fi fàdákà ṣe, nítorí a ka fàdákà nǹkan kan gbogbo ọjọ́ Solomoni. 22 Ọba ọkọ̀ Tarṣiṣi kan pẹ̀ọkọ̀ Hiramu Òkun. ̀̀kan ọdún mẹ́ta ni ọkọ̀ Tarṣiṣi ń , ó ń wúrà àti fàdákà, eyín erin àti ìnàkí àti ẹyẹ-ológe .

23 Solomoni ọba pọ̀ ọrọ̀ àti ọgbọ́n ju gbogbo àwọn ọba ayé lọ. 24 Gbogbo ayé ń ojú Solomoni láti gbọ́ ọgbọ́n Ọlọ́run ti fi i ọkàn. 25 ọdún ṣe ń gorí ọdún olúkúlùkù àwọn ń ń ̀bùn tirẹ̀ , ohun èlò fàdákà àti ohun èlò wúrà àti ̀, àti tùràrí olóòórùn dídùn, ẹṣin àti ìbáaka.

26 Solomoni kẹ̀kẹ́ àti ẹṣin jọ; ó ẹgbàáje (1,400) kẹ̀kẹ́ àti ẹgbàá mẹ́(12,000) ẹlẹ́ṣin, ó fi pamọ́ ìlú kẹ̀kẹ́ àti pẹ̀ọba Jerusalẹmu. 27 Ọba jẹ́ fàdákà pọ̀ Jerusalẹmu òkúta, àti igi kedari ni ó ṣe ó dàbí igi sikamore ń bẹ àfonífojì fún ̀pọ̀lọpọ̀. 28 A àwọn ẹṣin fún Solomoni láti Ejibiti àti láti Kue, oníṣòwò ọba wọ́n láti Kue fún owó. 29 Wọ́n ń kẹ̀kẹ́ kan gòkè láti Ejibiti fún ẹgbẹ̀ta (600) ṣékélì fàdákà àti ẹṣin kan fún àádọ́jọ. Bẹ́̀ ni wọ́n tún wọn fún ọba àwọn ọmọ Hiti àti ọba àwọn ọmọ Aramu.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também