Pular para o conteúdo
Publicidade

1 Ọba 15

Abijah ọba Juda

1 15.1,2,7: 2Ki 13.1,2. ọdún kejìdínlógún ìjọba Jeroboamu ọmọ Nebati, Abijah jẹ ọba lórí Juda, 2 ó jẹ ọba ọdún mẹ́ta Jerusalẹmu. Orúkọ ìyá rẹ̀ ni Maaka, ọmọbìnrin Absalomu.

3 Ó rìn nínú gbogbo ̀ṣẹ̀ baba rẹ̀ ti ṣáájú rẹ̀; ọkàn rẹ̀ pẹ̀Olúwa Ọlọ́run rẹ̀, gẹ́gẹ́ ọkàn Dafidi baba ńlá rẹ̀ ti ṣe. 4 Ṣùgbọ́n, nítorí i Dafidi Olúwa Ọlọ́run rẹ̀ fún un ìmọ́lẹ̀ kan Jerusalẹmu nípa gbígbé ọmọ rẹ̀ láti jẹ ọba ipò rẹ̀ àti láti fi ìdí Jerusalẹmu múlẹ̀. 5 Nítorí Dafidi ṣe èyí ó dára ojú Olúwa, kùnà láti pa gbogbo èyí Olúwa pàṣẹ fún un mọ́ ọjọ́ ayé rẹ̀ gbogbo; ṣe kìkì ̀ràn Uriah ará Hiti.

6 Ogun láàrín Rehoboamu àti Jeroboamu gbogbo ọjọ́ ayé Abijah. 7 ti ìyókù ìṣe Abijah, àti gbogbo èyí ó ṣe, a ha kọ wọ́n sínú ìwé ̀rọ̀ ọjọ́ àwọn ọba Juda? Ogun láàrín Abijah àti Jeroboamu. 8 15.8-12: 2Ki 14.1-5.Abijah sùn pẹ̀àwọn baba rẹ̀, a sin ín ìlú Dafidi. Asa ọmọ rẹ̀ jẹ ọba ipò rẹ̀.

Asa ọba Juda

9 ogún ọdún Jeroboamu ọba Israẹli, Asa jẹ ọba lórí Juda, 10 Ó jẹ ọba Jerusalẹmu ọdún mọ́kànlélógójì. Orúkọ ìyá ńlá rẹ̀ ni Maaka, ọmọbìnrin Absalomu.

11 Asa ṣe èyí ó dára lójú Olúwa, Dafidi baba rẹ̀ ti ṣe. 12 Ó àwọn ọkùnrin alágbèrè ojúbọ òrìṣà kúrò ilẹ̀ náà, ó gbogbo ère àwọn baba rẹ̀ ti ṣe kúrò. 13 15.13-22: 2Ki 15.16–16.6.Ó Maaka ìyá ńlá rẹ̀ kúrò láti máa ṣe ayaba, nítorí ó ère kan fún Aṣerah òrìṣà rẹ̀. Asa ère náà lulẹ̀, ó o àfonífojì Kidironi. 14 Ṣùgbọ́n àwọn ibi gíga kúrò, síbẹ̀ ọkàn Asa pẹ̀Olúwa ọjọ́ ayé rẹ̀ gbogbo. 15 Ó wúrà àti fàdákà àti àwọn ohun èlò òun àti baba rẹ̀ ti mímọ́ wọ ilé Olúwa.

16 Ogun láàrín Asa àti Baaṣa ọba Israẹli gbogbo ọjọ́ ayé wọn. 17 Baaṣa, ọba Israẹli gòkè lọ Juda, ó kọ́ Rama láti jẹ́ ẹnikẹ́ni jáde tàbí wọlé tọ Asa ọba lọ.

18 Nígbà náà ni Asa gbogbo fàdákà àti wúrà ó nínú ìṣúra ilé Olúwa àti ìṣúra ilé ọba. Ó fi àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ lọ́wọ́, ó rán wọn lọ ̀dọ̀ Beni-Hadadi ọmọ Tabrimoni, ọmọ Hesioni ọba Siria ó ń gbé Damasku. 19 Ó , "Jẹ́ májẹ̀ó láàrín èmi àti ìwọ, ó ti láàrín baba mi àti baba rẹ. ó, Èmi rán ọrẹ fàdákà àti wúrà . Ǹjẹ́ nísinsin yìí, da májẹ̀rẹ pẹ̀Baaṣa, ọba Israẹli, ó lọ kúrò lọ́dọ̀ mi."

20 Beni-Hadadi gba ti Asa ọba, ó rán àwọn alágbára olórí ogun rẹ̀ àwọn ìlú Israẹli. Ó ṣẹ́gun Ijoni, Dani àti Abeli-Beti-Maaka, àti gbogbo Kinnereti pẹ̀gbogbo ilẹ̀ Naftali. 21 Nígbà Baaṣa gbọ́ èyí, ó ṣíwọ́ kíkọ́ Rama, ó lọ kúrò Tirsa. 22 Nígbà náà ni Asa ọba kéde gbogbo Juda, ẹnìkan , wọ́n òkúta Rama kúrò àti igi rẹ̀, Baaṣa fi kọ́. Asa ọba fi wọ́n kọ́ Geba ti Benjamini àti Mispa.

23 15.23,24: 2Ki 16.12-14. ti ìyókù gbogbo ìṣe Asa, àti gbogbo agbára rẹ̀, àti gbogbo ohun ó ṣe, àti àwọn ìlú ó kọ́, a ha kọ wọ́n sínú ìwé ̀rọ̀ ọjọ́ àwọn ọba Juda? Ṣùgbọ́n, ìgbà ogbó rẹ̀, ààrùn ṣe é ẹsẹ̀ rẹ̀. 24 15.24: 2Ki 17.1.Asa sùn pẹ̀àwọn baba rẹ̀, a sin ín pẹ̀àwọn baba rẹ̀ ìlú Dafidi baba rẹ̀. Jehoṣafati ọmọ rẹ̀ jẹ ọba ipò rẹ̀.

Nadabu ọba Israẹli

25 Nadabu ọmọ Jeroboamu jẹ ọba lórí Israẹli ọdún kejì Asa ọba Juda, ó jẹ ọba lórí Israẹli ọdún méjì. 26 Ó ṣe búburú níwájú Olúwa, ó rìn ̀baba rẹ̀ àti nínú ̀ṣẹ̀ rẹ̀, èyí ó Israẹli .

27 Baaṣa ọmọ Ahijah ti ilé Isakari dìtẹ̀ i, Baaṣa kọlù ú Gibetoni, ìlú àwọn ará Filistini, nígbà Nadabu àti gbogbo Israẹli ti Gibetoni. 28 Baaṣa pa Nadabu ọdún kẹta Asa ọba Juda, ó jẹ ọba ipò rẹ̀.

29 Ó ṣe, ó ti bẹ̀rẹ̀ jẹ ọba ó pa gbogbo ilé Jeroboamu, ku ẹnìkan ń fún Jeroboamu, ṣùgbọ́n ó run gbogbo wọn, gẹ́gẹ́ ̀rọ̀ Olúwa, ó sọ nípa ọwọ́ ìránṣẹ́ rẹ̀ Ahijah ará Ṣilo. 30 Nítorí ̀ṣẹ̀ Jeroboamu ti ṣẹ̀ àti ó Israẹli ṣẹ̀, àti nítorí ó ti Olúwa Ọlọ́run Israẹli bínú.

31 ti ìyókù ìṣe Nadabu àti gbogbo ohun ó ṣe, a ha kọ wọ́n sínú ìwé ̀rọ̀ ọjọ́ àwọn ọba Israẹli? 32 Ogun láàrín Asa àti Baaṣa ọba Israẹli gbogbo ọjọ́ wọn.

Baaṣa ọba Israẹli

33 ọdún kẹta Asa ọba Juda, Baaṣa ọmọ Ahijah jẹ ọba lórí gbogbo Israẹli Tirsa, ó jẹ ọba ọdún mẹ́rìnlélógún. 34 Ó ṣe búburú níwájú Olúwa, ó rìn ̀Jeroboamu àti nínú ̀ṣẹ̀ rẹ̀, èyí ó ti Israẹli ṣẹ̀.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também