Pular para o conteúdo
Publicidade

Esekiẹli 29

Àsọtẹ́lẹ̀ òdì Ejibiti

1 29.1–32.32: Isa 19; Jr 46; Sk 14.18-19. ọjọ́ kejìlá, oṣù kẹwàá, ọdún kẹwàá, ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ : 2 "Ọmọ ènìyàn, kọjú Farao ọba Ejibiti ó sọ àsọtẹ́lẹ̀ i àti gbogbo Ejibiti. 3 Sọ̀rọ̀, ó , Báyìí Olúwa Olódùmarè :

" Èmi lòdì , Farao ọba Ejibiti

ìwọ ̀búburú ńlá inú òkun ó dùbúlẹ̀

àárín àwọn odò ṣíṣàn rẹ.

Èyí ó sọ , "Tèmi ni odò Naili;

èmi ni ó ṣe é fún ara mi."

4 Ṣùgbọ́n èmi yóò fi ìwọ̀ ẹnu rẹ

èmi yóò ẹja inú odò rẹ

gbogbo lẹ̀ mọ́ ìpẹ́ ara rẹ.

Èmi yóò ́ síta kúrò láàrín àwọn odò rẹ,

àti gbogbo ẹja odò rẹ yóò lẹ̀ mọ́ ìpẹ́ ara rẹ.

5 Èmi yóò sọ ́ aginjù

ìwọ àti gbogbo ẹja inú odò rẹ:

ìwọ yóò ṣubú gbangba oko

a yóò ṣà ́ jọ tàbí gbé sókè.

Èmi ti fi ṣe oúnjẹ fún àwọn ẹranko igbó

àti fún àwọn ẹyẹ ojú ̀run láti jẹ.

6 Nígbà náà gbogbo àwọn olùgbé ni Ejibiti yóò mọ , Èmi ni Olúwa.

" Ìwọ ti jẹ́ ̀ìyè fún ilé Israẹli. 7 Nígbà wọn fi ọwọ́ agbára wọn ́ . Ìwọ fọ́, ìwọ ya gbogbo èjìká wọn; nígbà wọn fi ara ́, ìwọ sẹ́, ìwọ gbogbo ̀gbẹ́ wọn gbọ̀n.

8 " Nítorí náà, èyí Olúwa Olódùmarè : Kíyèsi, Èmi yóò idà kan sórí rẹ yóò ènìyàn àti ẹran kúrò nínú rẹ. 9 Ilẹ̀ Ejibiti yóò di aginjù àti ahoro, nígbà náà wọn yóò mọ̀ èmi Olúwa.

" Nítorí ìwọ , "Tèmi ni odò Naili, Èmi ni mo ṣe é," 10 nítorí náà, mo lòdì àti àwọn odò rẹ, èmi yóò ilẹ̀ Ejibiti di píparun àti ahoro, pátápátá, láti Migdoli lọ Siene, ààlà ilẹ̀ Kuṣi. 11 ẹsẹ̀ ènìyàn tàbí ẹranko yóò gba ibẹ̀ kọjá; ẹni kankan gbé ibẹ̀ fún ogójì ọdún. 12 Èmi yóò sọ ilẹ̀ Ejibiti di ̀kan àárín àwọn ìlú ó di ahoro, fún ogójì ọdún, Èmi yóò fọ́n àwọn ara Ejibiti sáàárín àwọn orílẹ̀-èdè, èmi yóò wọn sáàárín gbogbo ilẹ̀.

13 " Ṣùgbọ́n báyìí Olúwa Olódùmarè : òpin ogójì ọdún, èmi yóò ṣa àwọn ará Ejibiti jọ láti ̀dọ̀ àwọn ènìyàn níbi a fọ́n wọn . 14 Èmi yóò tún ìgbèkùn Ejibiti padà bọ̀, èmi yóò wọn padà ilẹ̀ Paturosi, ilẹ̀ àwọn baba ńlá wọn. Wọn yóò níbẹ̀ ìjọba a rẹ̀ sílẹ̀. 15 Ibẹ̀ yóò jẹ́ ìjọba ó rẹlẹ̀ jùlọ nínú àwọn ìjọba, yóò gbé ara rẹ̀ ga mọ́ sórí àwọn orílẹ̀-èdè: nítorí èmi ni ó dín wọn , tiwọn yóò fi ṣe olórí àwọn orílẹ̀-èdè yòókù mọ́. 16 Ejibiti yóò jẹ orísun ìgbẹ́kẹ̀fún ilé Israẹli mọ́ ṣùgbọ́n, yóò jẹ́ ìrántí fún àìṣedéédéé wọn, nígbà yóò wọ́n fún ìrànlọ́wọ́. Nígbà náà, wọn yóò mọ̀ èmi ni Olúwa Olódùmarè.’ "

Èrè Nebukadnessari

17 Ó ṣe ọjọ́ kìn-ín-ní, oṣù kìn-ín-ní, ọdún kẹtàdínlọ́gbọ̀n, ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ : 18 "Ọmọ ènìyàn, Nebukadnessari ọba Babeli ogun rẹ sin ìrú ńlá fún Tire. Gbogbo orí , àti gbogbo èjìká , síbẹ̀, òun àti àwọn ogun rẹ̀, owó ̀gbà láti Tire fún wa, fún ìrú ti a ti sìn. 19 Nítorí náà, báyìí ni Olúwa Olódùmarè : Kíyèsi i, Èmi yóò fi Ejibiti fún Nebukadnessari ọba Babeli, òun yóò ọrọ̀ rẹ̀ lọ. Òun yóò bo ilé, yóò ṣe ìkógun ilẹ̀ náà gẹ́gẹ́ owó iṣẹ́ a san fún ológun rẹ̀. 20 Èmi ti fi Ejibiti fún un gẹ́gẹ́ èrè wàhálà rẹ̀ nítorí òun àti àwọn ológun rẹ ṣe é fún mi, ni Olúwa Olódùmarè .

21 "ọjọ́ náà, èmi yóò ìwo Israẹli ru jáde, èmi yóò fún ẹnu ̀rọ̀ àárín wọn. Nígbà náà ni wọn yóò mọ̀ èmi ni Olúwa."

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também