Pular para o conteúdo
Publicidade

Esekiẹli 32

Ìpohùnréré ẹkún fún Farao

1 ọjọ́ kìn-ín-ní, oṣù kejìlá, ọdún kejìlá, ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ : 2 "Ọmọ ènìyàn, ṣe ìpohùnréré ẹkún nítorí Farao ọba Ejibiti o fún un:

" Ìwọ dàbí kìnnìún láàrín àwọn orílẹ̀-èdè náà;

ìwọ dàbí ohun ̀búburú inú àwọn omi okun

to ń lọ káàkiri inú àwọn odò rẹ,

ìwọ fi ẹsẹ̀ rẹ tẹ omi

láti àwọn odò ẹrẹ̀.

3 " Èyí yìí Olúwa Olódùmarè :

" Pẹ̀̀pọ̀ ìpéjọ ènìyàn

èmi yóò da àwọ̀n mi ́

wọn yóò ́ sókè nínú àwọ̀n mi.

4 Èmi yóò ́ orí ilẹ̀

èmi yóò ́ sókè orí pápá gbangba.

Èmi yóò jẹ́ gbogbo ẹyẹ ojú ̀run ṣe

àtìpó orí rẹ.

Gbogbo àwọn ẹranko ayé yóò fi

ìwọra gbé ara wọn lórí rẹ.

5 Èmi yóò tan ẹran-ara rẹ sórí

àwọn òkè gíga

ìyókù ara rẹ wọn yóò fi kún

àwọn àárín àwọn òkè gíga.

6 ̀jẹ̀ rẹ ti ń sàn èmi yóò fi rin ilẹ̀ náà

gbogbo ̀orí àwọn òkè gíga,

àwọn àlàfo jíjìn wọn yóò kún fún ẹran-ara rẹ.

7 Nígbà mo fọ́n jáde, èmi yóò pa ̀run

àwọn ìràwọ̀ wọn yóò ṣókùnkùn;

èmi yóò fi ìkùùkuu bo oòrùn

òṣùpá yóò tan ìmọ́lẹ̀ rẹ̀.

8 Gbogbo ìmọ́lẹ̀ títàn ojú ̀run

ni èmi yóò ṣókùnkùn lórí rẹ;

èmi yóò òkùnkùn sórí ilẹ̀ rẹ,

ni Olúwa Olódùmarè .

9 Èmi yóò da ọkàn ̀pọ̀ àwọn ènìyàn

nígbà mo ìparun rẹ

àárín àwọn orílẹ̀-èdè ìwọ

í ì mọ̀.

10 Èmi yóò ̀pọ̀ àwọn ènìyàn dẹ́rùbà ́,

àwọn ọba wọn yóò wárìrì fún

ìbẹ̀pẹ̀ìpayà nítorí rẹ,

nígbà mo ju idà mi iwájú wọn.

ọjọ́ ìṣubú rẹ

̀kọ̀̀kan nínú wọn yóò wárìrì

gbogbo ìgbà fún ̀rẹ.

11 " Nítorí èyí yìí Olúwa Olódùmarè :

" Idà ọba Babeli

yóò orí rẹ,

12 Èmi yóò ìjọ ènìyàn rẹ ó

ipa idà àwọn alágbára ènìyàn ṣubú

àwọn orílẹ̀-èdè aláìláàánú jùlọ.

Wọn yóò ìgbéraga Ejibiti ,

gbogbo ìjọ rẹ a yóò ojú wọn bolẹ̀.

13 Gbogbo ẹran ̀sìn rẹ ni èmi yóò parun

̀gbẹ́ ̀pọ̀lọpọ̀ omi

i ṣe ẹsẹ̀ ènìyàn yóò tẹ ibẹ̀

ẹsẹ̀ ẹran ̀sìn yóò ibẹ̀ ni ẹrọ̀fọ̀.

14 Lẹ́yìn náà èmi yóò omi rẹ̀ tòrò

àwọn odò rẹ̀ o sàn epo,

ni Olúwa Olódùmarè .

15 Nígbà mo sọ Ejibiti di ahoro,

mo gbogbo ohun ó orí ilẹ̀ náà kúrò.

Nígbà mo àwọn olùgbé ibẹ̀ lulẹ̀,

nígbà náà wọn yóò mọ̀ èmi ni Olúwa.

16 "Èyí yìí ni ẹkún a yóò sun fún un. Àwọn ọmọbìnrin orílẹ̀-èdè yóò sun ún; nítorí Ejibiti àti gbogbo ìjọ rẹ, wọn yóò sun ún, Olúwa Olódùmarè ."

17 ọjọ́ kẹ́̀dógún oṣù, ọdún kejìlá, ̀rọ̀ Olúwa tọ : 18 "Ọmọ ènìyàn, pohùnréré ẹkún lórí Ejibiti o ránṣẹ́ ìsàlẹ̀ ilẹ̀ àti òun àti àwọn ọmọbìnrin orílẹ̀-èdè alágbára, pẹ̀àwọn o lọ ìsàlẹ̀, kòtò. 19 Sọ fún wọn, Ǹjẹ́ ìwọ ojúrere àwọn o lọ? Lọ ìsàlẹ̀ a tẹ́ àárín àwọn aláìkọlà náà.20 Wọn yóò ṣubú láàrín àwọn a fi idà pa. A fa idà yọ; jẹ́ a wọ́ Ejibiti kúrò pẹ̀gbogbo ìjọ rẹ̀. 21 Láti inú isà òkú alágbára í ṣe aṣáájú yóò sọ nípa Ejibiti àti àwọn àlejò rẹ̀, Wọn ti ìsàlẹ̀, wọn sùn pẹ̀aláìkọlà, pẹ̀àwọn a fi idà pa.

22 "Asiria níbẹ̀ pẹ̀gbogbo jagunjagun rẹ̀; àwọn isà òkú àwọn a ti pa i , gbogbo àwọn ó ti ipa idà ṣubú. 23 Isà òkú wọn ibi ó jinlẹ̀ gan an nínú kòtò. Gbogbo àwọn ó ti tan ̀ilẹ̀ alààyè a pa, ó ti ipa idà ṣubú.

24 "Elamu níbẹ̀, o isà òkú rẹ̀ pẹ̀gbogbo ogun rẹ̀. Gbogbo wọn ni a pa, àwọn ó ti ipa idà ṣubú. Gbogbo àwọn ó ti tan ̀ilẹ̀ alààyè lọ ìsàlẹ̀ láìkọlà abẹ́ ilẹ̀. Wọ́n gba ìtìjú wọn pẹ̀àwọn ó lọ ìsàlẹ̀ kòtò. 25 A ṣe ibùsùn fún un láàrín àwọn a pa, pẹ̀gbogbo ìjọ rẹ̀ ó isà òkú . Gbogbo wọn jẹ́ aláìkọlà, a fi idà pa. Nítorí a tan ̀wọn ilẹ̀ alààyè, wọn ru ìtìjú wọn pẹ̀àwọn ó lọ ìsàlẹ̀ kòtò; a tẹ́ wọn pẹ̀àwọn a pa.

26 "Meṣeki àti Tubali níbẹ̀, pẹ̀gbogbo ogun wọn isà òkú wọn . Gbogbo wọn jẹ́ aláìkọlà, wọ́n fi idà pa wọ́n nítorí ̀tiwọn tàn ilẹ̀ alààyè. 27 Wọn yóò dùbúlẹ̀ ti àwọn ó ṣubú nínú àwọn aláìkọlà, wọn sọ̀kalẹ̀ lọ ipò òkú pẹ̀ìhámọ́ra ogun wọn, wọ́n fi idà wọn rọ orí wọn. Ṣùgbọ́n àìṣedéédéé wọn yóò orí egungun wọnwọ́n tilẹ̀ jẹ́ ̀àwọn alágbára ilẹ̀ alààyè.

28 "Ìwọ náà, Farao, yóò ṣẹ, ti yóò dùbúlẹ̀ láàrín aláìkọlà, pẹ̀àwọn a fi idà pa.

29 "Edomu níbẹ̀, àwọn ọba rẹ̀ àti gbogbo ọmọbìnrin ọba; ó tilẹ̀ jẹ́ ó agbára, a tẹ́ wọn pẹ̀àwọn a fi idà pa. Wọn dùbúlẹ̀ pẹ̀aláìkọlà, pẹ̀àwọn ti o lọ sínú kòtò.

30 "Gbogbo àwọn ọmọ-aládé ilẹ̀ àríwá àti gbogbo àwọn ará Sidoni níbẹ̀; wọn lọ ìsàlẹ̀ pẹ̀àwọn a pa ìtìjú, ó tilẹ̀ jẹ́ wọn ṣe okùnfà ̀pẹ̀agbára wọn. Wọn sùn àìkọlà pẹ̀àwọn a fi idà pa, wọn ru ìtìjú wọn pẹ̀àwọn ó lọ ìsàlẹ̀ kòtò.

31 "Farao, òun àti gbogbo jagunjagun rẹ̀ yóò wọn, a yóò ú nínú nítorí gbogbo ogun rẹ̀ a fi idà pa, Olúwa Olódùmarè . 32 ó tilẹ̀ jẹ́ mo ti tan ̀ilẹ̀ alààyè, Farao àti gbogbo ogun rẹ̀ ni a yóò tẹ́ àárín aláìkọlà, pẹ̀àwọn a fi idà pa Olúwa Olódùmarè ."

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também