Pular para o conteúdo
Publicidade

Esekiẹli 21

Babeli idà Ọlọ́run fún ìdájọ́

1 ̀rọ̀ Olúwa tọ mi : 2 "Ọmọ ènìyàn, kọ ojú rẹ ìhà Jerusalẹmu, o wàásù lòdì ibi mímọ́. Sọ àsọtẹ́lẹ̀ ilẹ̀ Israẹli. 3 ó sọ fún un pe, Èyí yìí ni Olúwa , Èmi lòdì . Èmi yóò fa idà mi yọ kúrò nínú àkọ̀ rẹ̀, Èmi yóò olódodo àti ènìyàn búburú kúrò ni àárín yín. 4 Nítorí , èmi yóò olódodo àti olùṣe búburú kúrò, idà mi yóò jáde láti inú àkọ̀ rẹ̀ lòdì gbogbo ènìyàn láti gúúsù títí àríwá. 5 Nígbà náà gbogbo ènìyàn yóò mọ̀ , Èmi Olúwa ti yọ idà mi kúrò nínú àkọ̀ rẹ̀; yóò padà sínú rẹ̀ mọ́.’

6 "Nítorí náà, ìmí ̀dùn ìwọ ọmọ ènìyàn! ìmí ̀dùn pẹ̀ọkàn ìbànújẹ́ àti ̀dùn ọkàn kíkorò iwájú wọn. 7 wọ́n bi ́, , ni ó ìwọ fi ń ìmí ̀dùn?Ìwọ yóò , Nítorí ìròyìn ó ń bẹ. Gbogbo ọkàn ni yóò yọ́, gbogbo ọwọ́ ni yóò di aláìlera; gbogbo ọkàn yóò dákú, gbogbo eékún ni yóò di aláìlera omi?Ó ń bọ̀! Yóò wa ìmúṣẹ dandan, ni Olúwa Olódùmarè ."

8 ̀rọ̀ Olúwa si tún tọ̀ : 9 "Ọmọ ènìyàn, sọtẹ́lẹ̀ , èyí yìí Olúwa ,

" Idà kan, idà kan,

a pọ́n, a dán pẹ̀,

10 a pọ́n láti pa ènìyàn púpọ̀,

a dán an láti máa kọ mọ̀!

" Àwa o ha máa ṣe àríyá ̀gọ ọmọ mi? Idà gán gbogbo irú igi bẹ́̀.

11 " Idà a yàn láti pọ́n,

ó ṣe é gbámú;

a pọ́n ọn, a dán an,

ó ṣetán fún ọwọ́ àwọn apani.

12 Sọkún síta, ó pohùnréré ̀kún, ọmọ ènìyàn,

nítorí yóò sórí àwọn ènìyàn mi;

yóò sórí gbogbo ọmọ-aládé Israẹli

ìbẹ̀ńlá yóò sórí àwọn ènìyàn mi

nítorí idà náà;

nítorí náà lu oókan àyà rẹ.

13 " Ìdánwò yóò dandan. ̀aládé Juda èyí idà kẹ́gàn, tẹ̀síwájú mọ́ ń kọ́? Ni Olúwa Olódùmarè .

14 "Nítorí náà, ọmọ ènìyàn,

sọtẹ́lẹ̀ ó fi ọwọ́ lu ọwọ́.

Jẹ́ idà lu ara wọn lẹ́̀méjì,

kódà ̀̀mẹta.

Ó jẹ́ idà fún ìpànìyàn

idà fún ìpànìyàn lọ́pọ̀lọ́pọ̀,

yóò wọn mọ́ níhìn-ín àti lọ́hùnnún.

15 ọkàn ó yọ́

àwọn ó ṣubú le pọ̀,

mo ti gbé idà gbogbo bodè fún ìparun.

Háà! A ó kọ ìmọ̀nàmọ́,

a gbá a fún ìparun.

16 Ìwọ idà, ̀tún

o òsì

lọ ibikíbi ẹnu rẹ dojúkọ.

17 Èmi gan an yóò pàtẹ́wọ́

ìbínú mi yóò rẹlẹ̀.

Èmi Olúwa ti sọ̀rọ̀."

18 ̀rọ̀ Olúwa tọ mi : 19 "Ọmọ ènìyàn la ̀méjì fún idà ọba Babeli láti gbà, méjèèjì bẹ̀rẹ̀ láti ìlú kan náà. Ṣe àmì ìkóríta ̀ó lọ ìlú náà. 20 La ̀kan fún idà láti kọlu Rabba ti àwọn ará Ammoni òmíràn kọlu Juda, ó kọlu Jerusalẹmu ìlú olódi. 21 Nítorí ọba Babeli yóò dúró ni ìyànà ojú ̀, ìkóríta, láti máa lo àfọ̀ṣẹ. Yóò fi ọfà di ìbò, yóò béèrè lọ́wọ́ àwọn òrìṣà rẹ̀, òun yóò ṣe àyẹ̀̀dọ̀. 22 Nínú ọwọ́ ̀tún rẹ ni ìbò Jerusalẹmu yóò ti , ibi yóò ti gbé afárá kalẹ̀, láti pàṣẹ fún àwọn apànìyàn, láti ki wọn ìhó ogun láti gbé òòlù ẹnu-ọ̀ibodè, láti mọ odi, àti láti kọ́ ilé ìṣọ́. 23 Àfọ̀ṣẹ náà yóò dàbí àmì èké àwọn ó ti búra ìtẹríba fún un, ṣùgbọ́n òun yóò ran wọn létí ẹbí wọn yóò wọn lọ ìgbèkùn.

24 "Nítorí náà èyí ohun Olúwa Olódùmarè : Nítorí ti ̀yin ti ̀bi yín ìrántí nípa ìṣọ̀tẹ̀ gbangba, ṣíṣe àfihàn àwọn ̀ṣẹ̀ rẹ nínú gbogbo ohun ó ṣe, nítorí ̀yin ti ṣe èyí, a yóò yín ìgbèkùn.

25 " Ìwọ aláìmọ́ àti ẹni búburú ọmọ-aládé Israẹli, ẹni ti ọjọ́ rẹ̀ ti , ẹni àsìkò ìjìyà rẹ̀ ti góńgó, 26 èyí yìí ohun Olúwa Olódùmarè , ìwérí kúrò o gbé adé kúrò. ti tẹ́lẹ̀, ẹni ìgbéga ni a yóò rẹ̀ sílẹ̀. 27 Ìparun! Ìparun! Èmi yóò ṣé e ni ìparun! yóò padà bọ̀ sípò ṣe ó ̀dọ̀ ẹni ó ̀tọ́ láti ni in; òun ni èmi yóò fi fún.

28 21.28-32: El 25.1-7; Jr 49.1-6; Am 1.13-15; Sf 2.8-11. "Àti ìwọ, ọmọ ènìyàn sọtẹ́lẹ̀ ó , Èyí yìí ohun Olúwa Olódùmarè nípa àwọn ará Ammoni àti àbùkù wọn:

" Idà kan idà kan

á fa yọ fún ìpànìyàn

a dán láti fi ènìyàn ṣòfò

àti láti kọ ìmọ̀nàmọ́!

29 ó tilẹ̀ jẹ́ a èké nípa yín

àti àfọ̀ṣẹ èké nípa yín

a yóò gbé e àwọn ọrùn

ènìyàn búburú ti a ó pa,

àwọn ọjọ́ wọn ti ,

àwọn ọjọ́ ìjìyà wọn ti góńgó.

30 " idà padà sínú àkọ̀ rẹ̀.

Níbi a gbé ṣẹ̀yín,

ibi ̀yin ti ṣẹ̀ .

31 Níbẹ̀ ni èmi yóò ti ṣe ìdájọ́ yín,

èmi o fi èémí ìbínú gbígbóná

mi yín .

32 ̀yin yóò jẹ́ èpò fún iná náà,

a yóò ta ̀jẹ̀ yin sórí ilẹ̀ yín,

a yóò rántí yín mọ́;

nítorí Èmi Olúwa ó ti bẹ́̀.’ "

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também