Pular para o conteúdo
Publicidade

Esekiẹli 35

Àsọtẹ́lẹ̀ si Edomu

1 ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ : 2 "Ọmọ ènìyàn kọjú òkè Seiri; sọtẹ́lẹ̀ i, 3 o sọ , Èyí ni Olúwa Olódùmarè : Èmí lòdì , òkè Seiri, Èmi yóò na ọwọ́ mi síta ìlòdì , èmi yóò ó di ahoro. 4 Èmi yóò pa àwọn ìlú rẹ run, ìwọ yóò di ahoro. Nígbà náà ni ìwọ yóò mọ̀ èmi ni Olúwa.

5 " Nítorí ìwọ ààbò bo ̀tẹ̀ àtayébáyé, ìwọ fi Israẹli idà lọ́wọ́, àsìkò ìdààmú wọn, àsìkò ìjìyà wọn góńgó, 6 nítorí náà bi mo ti láààyè, ni Olúwa Olódùmarè , èmi yóò fi kalẹ̀ fún ìtàjẹ̀ sílẹ̀, ìtàjẹ̀ sílẹ̀ yóò lépa rẹ. Níwọ́n ìgbà ìwọ ti kórìíra ìtàjẹ̀ sílẹ̀, ìtàjẹ̀ sílẹ̀ yóò lépa rẹ. 7 Èmi yóò òkè Seiri di ahoro; ̀fọ̀ gbogbo àwọn ó ń lọ ó ń bọ̀ èmi yóò kúrò lára rẹ. 8 Èmi yóò fi àwọn a pa kún orí òkè rẹ, àwọn a fi idà pa yóò ṣubú orí òkè rẹ, àti àárín àwọn òkè rẹ. 9 Èmi yóò ó di ahoro títí láé, olùgbé ìlú rẹ. Nígbà náà ni ìwọ yóò mọ̀ èmi ni Olúwa.

10 " Nítorí ìwọ sọ , "Àwọn orílẹ̀-èdè àti ilẹ̀ méjì wọ̀nyí yóò jẹ́ tiwa, àwa yóò gbà wọ́n ìní," ó tilẹ̀ jẹ́ , Èmi Olúwa níbẹ̀, 11 nítorí náà níwọ̀n ìgbà mo ti láààyè, Olúwa Olódùmarè , èmi yóò hùwà ìbámu pẹ̀ìbínú àti owú o fihàn nínú ìkórìíra rẹ wọn, èmi yóò fi ara mi hàn àárín wọn, nígbà mo ṣe ìdájọ́ rẹ. 12 Nígbà náà ni ìwọ yóò mọ̀ , Èmi Olúwa ti gbọ́ gbogbo ohun ̀gàn ìwọ ti sọ lòdì àwọn òkè Israẹli náà. Ìwọ , "A sọ wọ́n di ahoro, a fi wọ́n fún wa láti run." 13 Ìwọ lérí mi, ó sọ̀rọ̀ lòdì láìsí ìdádúró, èmi gbọ́ . 14 Èyí ni Olúwa Olódùmarè : Nígbà gbogbo ayé ń yọ̀, èmi yóò ó di ahoro. 15 Nítorí ìwọ ń yọ̀ nígbà ìní ilé Israẹli di ahoro, bẹ́̀ gẹ́gẹ́ ni èmi yóò ṣe hùwà . Ìwọ yóò di ahoro, ìwọ òkè Seiri, ìwọ àti gbogbo ará Edomu. Nígbà náà, wọn yóò mọ̀ , Èmi ni Olúwa.’ "

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também